< Psalms 87 >

1 Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
Synům Chóre, žalm a píseň. Základ svůj na horách svatých.
2 Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
Milujeť Hospodin, totiž brány Sionské, nade všecky příbytky Jákobovy.
3 Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
Přeslavnéť jsou to věci, kteréž se o tobě hlásají, ó město Boží. (Sélah)
4 “Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
Připomínati budu Egypt a Babylon před svými známými, ano i Filistinské a Tyrské i Mouřeníny, že se tu každý z nich narodil.
5 Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
An i o Sionu praveno bude: Ten i onen jest rodem z něho, sám pak Nejvyšší utvrdí jej.
6 Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
Sečteť Hospodin při popisu národy, a dí, že tento se tu narodil. (Sélah)
7 Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”
Tou příčinou zpívají s plésáním o tobě všecky moci života mého.

< Psalms 87 >