< Psalms 87 >

1 Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Orin. Ó ti fi ìpìlẹ̀ rẹ̀ sọlẹ̀ sórí òkè mímọ́;
Hina Gode malei agolo sogebi amogai Ea moilale fi. Amo moilale fibi da Isala: ili soge amo ganodini moilai dialebe amo baligimu amola E da Yeluselemema bagadewane asigisa.
2 Olúwa fẹ́ràn ẹnu-ọ̀nà Sioni ju gbogbo ibùgbé Jakọbu lọ.
3 Ohun ológo ni a sọ nípa rẹ̀, ìlú Ọlọ́run,
Gode Ea Moilai Bai Bagade fi! Noga: idafa liligi E da dilima sia: be amo nabima.
4 “Èmi ó dárúkọ Rahabu àti Babeli láàrín àwọn tí ó jẹ́wọ́ mi: Filistia pẹ̀lú, àti Tire, pẹ̀lú Kuṣi, yóò sọ pé, ‘Èyí ni a bí ní Sioni.’”
“Na da fifi asi gala, amo da Na sia: nababe amo dedena dasea, Na da Idibidi amola Ba: bilone ela dedemu. Amola Na da Filisidia, Daia amola Idioubia amo Yelusaleme soge fifilai ilima gilisili idimu.”
5 Nítòótọ́, ti Sioni ni a ó sọ, “Eléyìí àti eléyìí ni a bí nínú rẹ̀, àti Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo ni yóò fìdí rẹ̀ múlẹ̀.”
Saione Goumi ea hou olelema: ne, ilia da amane sia: mu, ‘Fifi asi gala da amogai dialumu da defea. Amola Hina Bagadedafa da Saione amoga gasa imunu.’
6 Olúwa yóò kọ nínú àkọsílẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀: “Eléyìí ni a bí ní Sioni.”
Hina Gode da fifi asi gala huluane dedesa sa: ili, ili huluane Yelusaleme fidafa hamoi dagoi dedene legemu.
7 Àti àwọn olórin àti àwọn tí ń lu ohun èlò orin yóò wí pé, “Gbogbo orísun mi ń bẹ nínú rẹ.”
Ilia da gosa: le iaha amola amane gesami hea: sa, “Saione amo ganodini da hahawane dogolegesu hou huluane ea bai diala.”

< Psalms 87 >