< Psalms 86 >

1 Àdúrà ti Dafidi. Gbọ́, Olúwa, kí o sì dá mi lóhùn, nítorí mo jẹ́ tálákà àti aláìní.
Beka indlebe yakho, Nkosi, ungiphendule, ngoba ngingumyanga, ngiyaswela.
2 Dáàbò bò ayé mi, nítorí a ti yà mí sọ́tọ̀ fún ọ: ìwọ ni Ọlọ́run mi, gbà ìránṣẹ́ rẹ là tí ó gbẹ́kẹ̀lé ọ.
Londoloza umphefumulo wami, ngoba ngiyamesaba uNkulunkulu; wena Nkulunkulu wami, sindisa inceku yakho ekuthembayo.
3 Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń pè ọ́ ní gbogbo ọjọ́.
Woba lesihawu kimi, Nkosi, ngoba ngikhala kuwe usuku lonke.
4 Mú ayọ̀ wà fún ìránṣẹ́ rẹ, nítorí ìwọ, Olúwa, ni mo gbé ọkàn mí sókè sí.
Thokozisa umphefumulo wenceku yakho, ngoba kuwe, Nkosi, ngiyawuphakamisela umphefumulo wami.
5 Ìwọ ń dáríjì, ìwọ sì dára, Olúwa, ìwọ sì ṣàánú fún gbogbo àwọn tí ń ké pè ọ́.
Ngoba wena, Nkosi, ulungile, ungothethelelayo; umkhulu emuseni kubo bonke abakubizayo.
6 Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa; tẹ́tí sí ẹkún mi fún àánú.
Beka indlebe, Nkosi, emkhulekweni wami; ulalele ilizwi lokuncenga kwami.
7 Ní ọjọ́ ìpọ́njú mi èmi yóò pè ọ́, nítorí ìwọ yóò dá mi lóhùn.
Ngosuku lokuhlupheka kwami ngizakhala kuwe, ngoba uzangiphendula.
8 Nínú àwọn òrìṣà kò sí ẹni tí ó dàbí i rẹ, Olúwa: kò sí àwọn iṣẹ́ tí a lè fiwé tìrẹ.
Kakho ofanana lawe phakathi kwabonkulunkulu, Nkosi, njalo enjengemisebenzi yakho kayikho.
9 Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ dá yóò wá láti wá jọ́sìn níwájú rẹ, Olúwa; wọn ó mú ògo wà fún orúkọ rẹ̀.
Izizwe zonke ozenzileyo zizakuza zikhothame phambi kwakho, Nkosi, zidumise ibizo lakho.
10 Nítorí pé ìwọ tóbi, ìwọ sì ń ṣe ohun ìyanu; ìwọ nìkan ni Ọlọ́run.
Ngoba wena umkhulu, wenza izinto ezimangalisayo, unguNkulunkulu wena wedwa.
11 Kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, Olúwa, èmi ó sì máa rìn nínú òtítọ́ rẹ; fún mi ní ọkàn tí kì í yapa, kí èmi kí ó ba lè bẹ̀rù orúkọ rẹ.
Ngifundisa indlela yakho, Nkosi, ngizahamba eqinisweni lakho; hlanganisa inhliziyo yami ukuze yesabe ibizo lakho.
12 Èmi ó yìn ọ́, Olúwa Ọlọ́run mi, pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi; èmi ó fògo fún orúkọ rẹ títí láé.
Ngizakudumisa, Nkosi Nkulunkulu wami, ngenhliziyo yami yonke; ngilidumise ibizo lakho kuze kube nininini.
13 Nítorí títóbi ni ìfẹ́ rẹ si mi; ìwọ ti gbà mí kúrò nínú ọ̀gbun isà òkú. (Sheol h7585)
Ngoba umusa wakho phezu kwami mkhulu; njalo wakhulula umphefumulo wami esihogweni esingaphansi kakhulu. (Sheol h7585)
14 Àwọn onígbèéraga ń dojúkọ mí, Ọlọ́run; àti ìjọ àwọn alágbára ń wá ọkàn mi kiri, wọn kò sì fi ọ́ pè.
Nkulunkulu, abazigqajayo bangivukele, lemibuthano yabalobudlwangudlwangu idinga umphefumulo wami; njalo kabakubekanga phambi kwabo.
15 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, jẹ́ aláàánú àti Ọlọ́run olójúrere, Ó lọ́ra láti bínú, Ó sì pọ̀ ní ìfẹ́ àti òtítọ́.
Kodwa wena, Nkosi, unguNkulunkulu olozwelo, lolesisa, ophuza ukuthukuthela, lomkhulu emuseni leqinisweni.
16 Yípadà sí mi kí o sì ṣàánú fún mi; fún àwọn ènìyàn rẹ ní agbára kí o sì gba ọ̀dọ́mọkùnrin ìránṣẹ́bìnrin rẹ là.
Phendukela kimi, ungihawukele; uyiphe inceku yakho amandla akho, usindise indodana yencekukazi yakho.
17 Fi àmì hàn mí fún rere, kí àwọn tí ó kórìíra mi lè ri, kí ojú lè tì wọ́n, nítorí ìwọ Olúwa ni ó ti tù mí nínú.
Ngenzela isiboniso sokuhle, ukuze labo abangizondayo babone bayangeke, ngoba wena, Nkosi, ungisizile wangiduduza.

< Psalms 86 >