< Psalms 86 >
1 Àdúrà ti Dafidi. Gbọ́, Olúwa, kí o sì dá mi lóhùn, nítorí mo jẹ́ tálákà àti aláìní.
Drottinn, líttu til mín! Hlustaðu á bæn mína! Svaraðu mér því að ég er í nauðum staddur.
2 Dáàbò bò ayé mi, nítorí a ti yà mí sọ́tọ̀ fún ọ: ìwọ ni Ọlọ́run mi, gbà ìránṣẹ́ rẹ là tí ó gbẹ́kẹ̀lé ọ.
Bjargaðu mér frá dauða, því að ég tilheyri þér. Frelsaðu mig, því að ég treysti þér og hlýði.
3 Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń pè ọ́ ní gbogbo ọjọ́.
Miskunna mér, Drottinn. Ég mæni til þín og vona á þig liðlangan daginn.
4 Mú ayọ̀ wà fún ìránṣẹ́ rẹ, nítorí ìwọ, Olúwa, ni mo gbé ọkàn mí sókè sí.
Drottinn, leyfðu mér að gleðjast því að ég tilbið þig einan.
5 Ìwọ ń dáríjì, ìwọ sì dára, Olúwa, ìwọ sì ṣàánú fún gbogbo àwọn tí ń ké pè ọ́.
Drottinn, þú ert mildur og góður og fús að fyrirgefa, gæskuríkur við alla sem ákalla þig.
6 Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa; tẹ́tí sí ẹkún mi fún àánú.
Heyr þú bæn mína Drottinn, því að ég ákalla þig í neyð minni.
7 Ní ọjọ́ ìpọ́njú mi èmi yóò pè ọ́, nítorí ìwọ yóò dá mi lóhùn.
Þegar ég er í vanda staddur hrópa ég til þín því að þú hjálpar mér.
8 Nínú àwọn òrìṣà kò sí ẹni tí ó dàbí i rẹ, Olúwa: kò sí àwọn iṣẹ́ tí a lè fiwé tìrẹ.
Enginn hinna heiðnu guða stenst samjöfnuð við þig! Þín verk eru engu lík!
9 Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ dá yóò wá láti wá jọ́sìn níwájú rẹ, Olúwa; wọn ó mú ògo wà fún orúkọ rẹ̀.
Þjóðirnar – þú skapaðir þær allar – munu koma og lúta þér. Þær munu lofa þitt háa og heilaga nafn
10 Nítorí pé ìwọ tóbi, ìwọ sì ń ṣe ohun ìyanu; ìwọ nìkan ni Ọlọ́run.
því að þú ert mikill og gerir furðuverk. Þú einn ert Guð!
11 Kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, Olúwa, èmi ó sì máa rìn nínú òtítọ́ rẹ; fún mi ní ọkàn tí kì í yapa, kí èmi kí ó ba lè bẹ̀rù orúkọ rẹ.
Sýndu mér, Drottinn, hvert þú vilt senda mig og þangað mun ég fara, því það er vegur sannleikans. Ó, að ég gæti tignað þig af heilu hjarta og hreinni samvisku!
12 Èmi ó yìn ọ́, Olúwa Ọlọ́run mi, pẹ̀lú gbogbo ọkàn mi; èmi ó fògo fún orúkọ rẹ títí láé.
Ég lofa þig Drottinn Guð minn af öllu hjarta. Ég vil vegsama nafn þitt að eilífu.
13 Nítorí títóbi ni ìfẹ́ rẹ si mi; ìwọ ti gbà mí kúrò nínú ọ̀gbun isà òkú. (Sheol )
Mikill er kærleikur þinn! Þú ert mér alltaf svo góður! Þú frelsaðir mig úr djúpi heljar. (Sheol )
14 Àwọn onígbèéraga ń dojúkọ mí, Ọlọ́run; àti ìjọ àwọn alágbára ń wá ọkàn mi kiri, wọn kò sì fi ọ́ pè.
Ofstopamenn rísa gegn mér. Guðlaus illmenni vilja ryðja mér burt.
15 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, jẹ́ aláàánú àti Ọlọ́run olójúrere, Ó lọ́ra láti bínú, Ó sì pọ̀ ní ìfẹ́ àti òtítọ́.
En þú, Drottinn, ert miskunnsamur Guð, seinn til reiði, langlyndur og trúr.
16 Yípadà sí mi kí o sì ṣàánú fún mi; fún àwọn ènìyàn rẹ ní agbára kí o sì gba ọ̀dọ́mọkùnrin ìránṣẹ́bìnrin rẹ là.
Líttu til mín í náð og styrktu mig. Ég er þjónn þinn, frelsaðu mig.
17 Fi àmì hàn mí fún rere, kí àwọn tí ó kórìíra mi lè ri, kí ojú lè tì wọ́n, nítorí ìwọ Olúwa ni ó ti tù mí nínú.
Gefðu mér tákn um að þú elskir mig. Þegar óvinir mínir sjá það, munu þeir blygðast sín því að þú hjálpar mér og huggar mig.