< Psalms 85 >

1 Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Ìwọ fi ojúrere hàn fún ilé rẹ, Olúwa; ìwọ mú ohun ìní Jakọbu bọ̀ sí ipò.
Neghmichilerning béshigha tapshurulup oqulsun dep, Korahning oghulliri üchün yézilghan küy: — Sen Öz zémininggha iltipat körsitip, Yaqupni sürgünlüktin qayturghaniding, i Perwerdigar.
2 Ìwọ dárí àìṣedéédéé àwọn ènìyàn rẹ jì ìwọ sì bó ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́lẹ̀. (Sela)
Xelqingning qebihlikini kechürüm qilip, Barliq gunahlirini yapqaniding. (Sélah)
3 Ìwọ fi àwọn ìbínú rẹ sápá kan ìwọ sì yípadà kúrò nínú ìbínú gbígbóná rẹ.
Sen pütün qehringni ichingge qayturuwélip, Ghezipingning esheddiylikidin yan’ghanidingsen.
4 Yí wa padà, Ọlọ́run ìgbàlà wa, kí o sì yí ìbínú rẹ̀ padà kúrò lọ́dọ̀ wa.
Emdi bizni Öz yéninggha qayturghaysen, i nijatliqimiz bolghan Xuda! Bizge bolghan achchiqinggha hay bergeysen!
5 Ìwọ yóò ha máa bínú sí wa títí láé? Ìwọ yóò ha mú ìbínú rẹ pẹ́ yí gbogbo ìran ká?
Sen bizge ebediy ghezeplinemsen? Ewladtin-ewladqiche ghezipingni sozamsen?
6 Ìwọ kì yóò ha sọ wá jí padà mọ́, pé kí àwọn ènìyàn rẹ lè yọ nínú rẹ?
Xelqing Özüngdin shadlinishi üchün, Bizni qaytidin yéngilimamsen?
7 Fi ìfẹ́ rẹ tí kò le è kùnà hàn wá, Olúwa, kí o sì fún wa ní ìgbàlà rẹ.
Bizge özgermes muhebbitingni körsetkeysen, i Perwerdigar, Bizge nijatliqingni ata qilghaysen!
8 Èmi ó gbọ́ ohun tí Olúwa Ọlọ́run yóò wí; ó ṣèlérí àlàáfíà fún àwọn ènìyàn rẹ̀, àní ẹni mímọ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n má ṣe jẹ́ kí wọn padà sí àìmoye.
Tengri Perwerdigarning némilerni deydighanliqigha qulaq salay; Chünki U Öz xelqige, Öz mömin bendilirige aman-xatirjemlikni sözleydu; Ular yene hamaqetlikke qaytmisun!
9 Nítòótọ́ ìgbàlà rẹ̀ súnmọ́ àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, pé kí ògo rẹ̀ kí ó lè gbé ní ilẹ̀ wa.
Zéminimizda shan-shöhretning turushi üchün, Derheqiqet, Uningdin eyminidighanlargha Uning nijatliqi yéqindur;
10 Ìfẹ́ àti òtítọ́ parapọ̀; òdodo àti àlàáfíà fẹnu ko ara wọn.
Özgermes muhebbet we heqiqet özara körüshti; Heqqaniyet we aman-xatirjemlik bir-birini söyüshti;
11 Òtítọ́ ń sun jáde láti ilẹ̀ wá òdodo sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run.
Heqiqet yerdin ünüp chiqmaqta, Heqqaniyet ershlerdin qaraydu.
12 Olúwa yóò fi ohun dídára fún ni nítòótọ́, ilẹ̀ wa yóò sì mú ìkórè rẹ̀ jáde.
Perwerdigar beriket béridu, Zéminimiz hosulini béridu;
13 Òdodo síwájú rẹ lọ o sì pèsè ọ̀nà fún ìgbésẹ̀ rẹ̀.
Heqqaniyet Uning aldida mangidu, Uning qedemlirige yol hazirlaydu!

< Psalms 85 >