< Psalms 85 >

1 Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Ìwọ fi ojúrere hàn fún ilé rẹ, Olúwa; ìwọ mú ohun ìní Jakọbu bọ̀ sí ipò.
Przewodnikowi chóru. Psalm dla synów Korego. PANIE, okazałeś łaskę swej ziemi, przyprowadziłeś z niewoli Jakuba.
2 Ìwọ dárí àìṣedéédéé àwọn ènìyàn rẹ jì ìwọ sì bó ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́lẹ̀. (Sela)
Przebaczyłeś nieprawość twego ludu, zakryłeś wszystkie ich grzechy. (Sela)
3 Ìwọ fi àwọn ìbínú rẹ sápá kan ìwọ sì yípadà kúrò nínú ìbínú gbígbóná rẹ.
Uśmierzyłeś całe swoje zagniewanie, odwróciłeś się od zapalczywości twojego gniewu.
4 Yí wa padà, Ọlọ́run ìgbàlà wa, kí o sì yí ìbínú rẹ̀ padà kúrò lọ́dọ̀ wa.
Odnów nas, Boże naszego zbawienia, i odwróć od nas swój gniew.
5 Ìwọ yóò ha máa bínú sí wa títí láé? Ìwọ yóò ha mú ìbínú rẹ pẹ́ yí gbogbo ìran ká?
Czy wiecznie będziesz się na nas gniewać? Czy rozciągniesz swój gniew na wszystkie pokolenia?
6 Ìwọ kì yóò ha sọ wá jí padà mọ́, pé kí àwọn ènìyàn rẹ lè yọ nínú rẹ?
Czy nie ożywisz nas na nowo, aby twój lud rozradował się w tobie?
7 Fi ìfẹ́ rẹ tí kò le è kùnà hàn wá, Olúwa, kí o sì fún wa ní ìgbàlà rẹ.
PANIE, okaż nam twoje miłosierdzie i daj nam swoje zbawienie.
8 Èmi ó gbọ́ ohun tí Olúwa Ọlọ́run yóò wí; ó ṣèlérí àlàáfíà fún àwọn ènìyàn rẹ̀, àní ẹni mímọ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n má ṣe jẹ́ kí wọn padà sí àìmoye.
Posłucham, co będzie mówił Bóg, PAN; zaprawdę, ogłosi pokój swojemu ludowi i swoim świętym, aby tylko nie wracali do [swojej] głupoty.
9 Nítòótọ́ ìgbàlà rẹ̀ súnmọ́ àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, pé kí ògo rẹ̀ kí ó lè gbé ní ilẹ̀ wa.
Doprawdy jego zbawienie jest blisko tych, którzy się go boją, [aby jego] chwała zamieszkała w naszej ziemi.
10 Ìfẹ́ àti òtítọ́ parapọ̀; òdodo àti àlàáfíà fẹnu ko ara wọn.
Miłosierdzie i prawda spotkają się ze sobą, sprawiedliwość i pokój ucałują się.
11 Òtítọ́ ń sun jáde láti ilẹ̀ wá òdodo sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run.
Prawda wyrośnie z ziemi, a sprawiedliwość wyjrzy z nieba.
12 Olúwa yóò fi ohun dídára fún ni nítòótọ́, ilẹ̀ wa yóò sì mú ìkórè rẹ̀ jáde.
PAN też obdarzy [tym, co] dobre, a nasza ziemia wyda swój plon.
13 Òdodo síwájú rẹ lọ o sì pèsè ọ̀nà fún ìgbésẹ̀ rẹ̀.
Sprawiedliwość przed nim pójdzie i będzie wytyczać drogę jego krokom.

< Psalms 85 >