< Psalms 84 >

1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti gittiti. Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Ibùgbé rẹ̀ ti lẹ́wà tó, Olúwa àwọn ọmọ-ogun!
Thaburi ya Ariũ a Kora Wee Jehova Mwene-Hinya-Wothe-rĩ, kaĩ gĩikaro gĩaku nĩ gĩthaka-ĩ!
2 Ọkàn mi ń ṣàfẹ́rí nítòótọ́ ó tilẹ̀ pòǹgbẹ fún àgbàlá Olúwa àyà mi àti ara mi ń kọrin ayọ̀ sí Ọlọ́run alààyè.
Muoyo wakwa wĩriragĩria mũno, ĩĩ o na ũkoorwo nĩ hinya, nĩ ũndũ wa kwĩrirĩria nja cia Jehova; ngoro yakwa na mwĩrĩ wakwa irakaĩra Mũrungu ũrĩa ũtũũraga muoyo.
3 Nítòótọ́ ológoṣẹ́ ri ilé, ẹyẹ alápáǹdẹ̀dẹ̀ tẹ́ ìtẹ́ fún ara rẹ̀, níbi tí yóò máa pa ọmọ rẹ̀ mọ́ sí: ibùgbé ní tòsí pẹpẹ rẹ̀, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ọba mí àti Ọlọ́run mi.
O na kanyoni-ka-nja nĩkoonete mũciĩ, nayo thũngũrũrũ ĩkeyonera gĩtara, harĩa ĩngĩikaria tũcui twayo, o hau hakuhĩ na kĩgongona gĩaku, Wee Jehova Mwene-Hinya-Wothe, o Wee Mũthamaki wakwa na Ngai wakwa.
4 Ìbùkún ní fún àwọn tí ó ń gbé inú ilé rẹ; wọn ó máa yìn ọ́ títí láé.
Kũrathimwo-rĩ, nĩ andũ arĩa matũũraga nyũmba yaku; matũũraga makũgoocaga.
5 Ìbùkún ni fún àwọn tí agbára wọn wà nínú rẹ àwọn tí wọ́n gbé ọkàn lé bíbẹ ibi mímọ́ wò.
Kũrathimwo-rĩ, nĩ andũ arĩa maheagwo hinya nĩwe, o arĩa matuĩte na ngoro ciao gũthiĩ Zayuni.
6 Àwọn tí ń la àfonífojì omijé lọ wọn sọ ọ́ di kànga àkọ́rọ̀ òjò sì fi ìbùkún bò ó.
Rĩrĩa megũtuĩkanĩria Gĩtuamba kĩa Baka, matũmaga kũgĩe na ithima; mbura ya maguna-ngʼombe o nayo ĩkũhumbĩraga na tũria twa maaĩ.
7 Wọ́n ń lọ láti ipa dé ipá títí tí ọ̀kọ̀ọ̀kan fi farahàn níwájú Ọlọ́run ní Sioni.
Mathiiaga magĩkĩragĩrĩria kũgĩa na hinya, nginya o mũndũ o mũndũ agakinya mbere ya Ngai kũu Zayuni.
8 Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa Ọlọ́run Alágbára; tẹ́tí sí mi, Ọlọ́run Jakọbu.
Igua ihooya rĩakwa, Wee Jehova Ngai-Mwene-Hinya-Wothe; thikĩrĩria, Wee Ngai wa Jakubu.
9 Wo asà wa, Ọlọ́run; fi ojú àánú wò àwọn ẹni àmì òróró rẹ.
Wee Ngai, ta rora ngo iitũ; tiirĩra ũrĩa waku ũitĩrĩirie maguta gĩthiithi.
10 Dídára ní ọjọ́ kan ní ààfin rẹ ju ẹgbẹ̀rún ọjọ́ lọ; èmi o kúkú máa ṣe aṣọ́nà nínú ilé Ọlọ́run mi jù láti gbé ní àgọ́ àwọn ènìyàn búburú.
Kaba mũthenya ũmwe nja-inĩ ciaku, gũkĩra gũikara mĩthenya ngiri handũ hangĩ o hothe; kaba ngorwo ndĩ mũrangĩri wa kĩhingo kĩa nyũmba ya Ngai wakwa, gũkĩra ndũũre thĩinĩ wa hema cia andũ arĩa aaganu.
11 Nítorí Olúwa Ọlọ́run jẹ́ òòrùn àti asà; Olúwa fún ni ní ojúrere àti ọlá; kò sí ohun rere kan tí yóò fàsẹ́yìn fún àwọn tí ó rìn ní àìlábùkù.
Nĩgũkorwo Jehova Ngai nĩ riũa na ngo; Jehova nĩarĩtũtugaga na agatwĩka maũndũ mega; arĩa mĩthiĩre yao ĩtarĩ ũcuuke ndarĩ ũndũ mwega angĩmaima.
12 Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí ó gbẹ́kẹ̀lé ọ.
Wee Jehova Mwene-Hinya-Wothe, kũrathimwo nĩ mũndũ ũrĩa ũkwĩhokaga.

< Psalms 84 >