< Psalms 82 >

1 Saamu ti Asafu. Ọlọ́run ń ṣàkóso nínú ìpéjọpọ̀ ńlá, ó ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn “ọlọ́run òrìṣà”.
Psalm Asafowy. Bóg stoi w zgromadzeniu Bożem, a w pośród bogów sądzi i mówi:
2 “Yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò máa gbèjà àwọn aláìṣòdodo kí ó sì ṣe ojú ìṣáájú sí àwọn ènìyàn búburú?
Dokądże będziecie niesprawiedliwie sądzić, a osoby niezbożników przyjmować? (Sela)
3 Gbèjà àwọn aláìlágbára àti aláìní baba; ṣe ìtọ́jú ẹ̀tọ́ àwọn aláìní àti ẹni ìnilára.
Czyńcie sprawiedliwość ubogiemu i sierotce; utrapionego i niedostatecznego usprawiedliwiajcie.
4 Gba àwọn aláìlágbára àti aláìní; gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú.
Wyrwijcie chudzinę i nędznego, a z ręki niepobożnej wyrwijcie go.
5 “Wọn kò mọ̀ ohun kankan, wọn kò lóye ohun kankan. Wọn ń rìn kiri nínú òkùnkùn; à si mí gbogbo ìpìlẹ̀ ayé.
Lecz oni nic nie wiedzą, ani rozumieją; w ciemnościach ustawicznie chodzą; zaczem się zachwiały wszystkie grunty ziemi.
6 “Mo wí pé, ‘Ẹyin ní “Ọlọ́run òrìṣà”; ẹ̀yin ní gbogbo ọmọ Ọ̀gá-ògo jùlọ.’
Jam rzekł: Bogowieście, a synami Najwyższego wy wszyscy jesteście.
7 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ó kú bí ènìyàn lásán; ẹ̀yin ó ṣubú bí ọ̀kan nínú ọmọ-aládé.”
A wszakże jako i inni ludzie pomrzecie, a jako jeden z książąt upadniecie.
8 Dìde, Ọlọ́run, ṣe ìdájọ́ ayé, nítorí gbogbo orílẹ̀-èdè ni ìní rẹ.
Powstańże, o Boże! a sądź ziemię; albowiem ty dziedzicznie trzymasz wszystkie narody.

< Psalms 82 >