< Psalms 81 >

1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti gittiti. Ti Asafu. Kọrin sókè sí Ọlọ́run agbára wa ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọ́run Jakọbu!
Asafa dziesma, dziedātāju vadonim uz Ģittit. Dziediet priecīgi Dievam, mūsu stiprumam, gavilējiet Jēkaba Dievam.
2 Ẹ mú orin mímọ́, kí ẹ sì mú ìlù wá, tẹ dùùrù dídùn pẹ̀lú ohun èlò orin mímọ́.
Uzdziedat dziesmas un dodiet šurp bungas, mīlīgas kokles ar stabulēm.
3 Ẹ fún ìpè ní oṣù tuntun àní nígbà tí a yàn; ní ọjọ́ àjọ wa tí ó ní ìrònú.
Pūtiet trumetes jaunā mēnesī, pilnā mēnesī, mūsu svētku laikā.
4 Èyí ni àṣẹ fún Israẹli, àti òfin Ọlọ́run Jakọbu.
Jo tas ir likums iekš Israēla, tiesa no Jēkaba Dieva.
5 Ó fi múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà fún Josẹfu nígbà tí ó la ilẹ̀ Ejibiti já. Níbi tí a ti gbọ́ èdè tí kò yé wa.
To Viņš licis par liecību iekš Jāzepa, kad izgāja pār Ēģiptes zemi, kad es dzirdēju valodu, ko nesapratu.
6 Ó wí pé, “Mo gbé àjàgà kúrò ní èjìká yín, a tú ọwọ́ wọn sílẹ̀ kúrò nínú apẹ̀rẹ̀.
“Viņa kamiešiem Es esmu atņēmis nastu, un viņa rokas atsvabinājis no nestavas.
7 Nínú ìnilára ni ẹ pè mo sì gbà yín là, mo dá a yín lóhùn nínú ìkọ̀kọ̀ àrá, mo dán an yín wò ní odò Meriba. (Sela)
Kad tu Mani piesauci bēdās, tad Es tevi izglābu; Es tevi paklausīju, paslēpies pērkona padebešos, Es tevi pārmanīju pie bāršanās ūdens.
8 “Gbọ́, ẹ̀yin ènìyàn mi, èmi ó sì kìlọ̀ fún un yín, bí ìwọ bá fetí sí mi, ìwọ Israẹli.
Klausāties, Mani ļaudis, Es jums došu liecību; Israēl, kaut tu Mani klausītu!
9 Ẹ̀yin kì yóò ní Ọlọ́run ilẹ̀ mìíràn láàrín yín; ẹ̀yin kì yóò foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run àjèjì.
Lai tavā starpā nav cita Dieva, un tev nebūs pielūgt svešu Dievu.
10 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, ẹni tí ó mú un yín jáde láti Ejibiti. Ẹ la ẹnu yín gbòòrò, èmi yóò sì kún un.
Es esmu Tas Kungs, tavs Dievs, kas tevi izvedis no Ēģiptes zemes; atplet savu muti, lai Es to pildu.
11 “Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi kì yóò gbọ́ tèmi; Israẹli kò ní tẹríba fún mi.
Bet Mani ļaudis neklausa Manu balsi un Israēlim Manis negribās.
12 Nítorí náà ni mo ṣe fi wọ́n fún ọkàn líle wọn láti máa rìn ní ọ̀nà ẹ̀tàn wọn.
Tad Es tos arī esmu pametis viņu cietam sirds prātam, ka tie staigā pēc saviem padomiem.
13 “Bí àwọn ènìyàn mi yóò bá gbọ́ tèmi bí Israẹli yóò bá tẹ̀lé ọ̀nà mi,
Kaut Mani ļaudis Man klausītu, un Israēls staigātu uz Maniem ceļiem!
14 ní kánkán ni èmi yóò ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá wọn kí n sì yí ọwọ́ mi padà sí ọ̀tá wọn!
Es pazemotu viņu ienaidniekus drīz un grieztu Savu roku pret viņu spaidītājiem.
15 Àwọn tí ó kórìíra Olúwa yóò tẹríba níwájú rẹ̀. Ìjìyà wọn yóò sì pẹ́ títí láé.
Kas To Kungu ienīst, tiem bija Viņam padoties, tad tie mūžīgi pastāvētu.
16 Ṣùgbọ́n a ó fi ọkà tí ó dára bọ́ ọ yín èmi ó tẹ́ ẹ yín lọ́rùn pẹ̀lú oyin inú àpáta.”
Un Viņš tos barotu ar briedušiem kviešiem, un ar medu no akmens kalna Es tevi pieēdinātu.”

< Psalms 81 >