< Psalms 81 >
1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti gittiti. Ti Asafu. Kọrin sókè sí Ọlọ́run agbára wa ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọ́run Jakọbu!
Anumzamo'a Agra tagri hankaveti mani'neanki zagame huta agi'a erisga hanune. Jekopu Anumzamofontega muse zagamera huta agi'a erisga hiho?
2 Ẹ mú orin mímọ́, kí ẹ sì mú ìlù wá, tẹ dùùrù dídùn pẹ̀lú ohun èlò orin mímọ́.
Zgamera nehuta nasenasepana neheta, knare ageru'ma neria hapu zavenane laeri zavenanena aheho.
3 Ẹ fún ìpè ní oṣù tuntun àní nígbà tí a yàn; ní ọjọ́ àjọ wa tí ó ní ìrònú.
Kasefa ikama eme antesigeta sipisipi afu'mofo paziveteti ufena nereta, ikamo'ma zarama vagehinigeta, ra ne'za kreno nekna egahianki, ne'zana kreta neneta musenkase hiho.
4 Èyí ni àṣẹ fún Israẹli, àti òfin Ọlọ́run Jakọbu.
Ama'i Israeli vahe'mofo trake, Jekopu Anumzamo'ma Israeli vahe'motama tami'nea kasegene trake.
5 Ó fi múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà fún Josẹfu nígbà tí ó la ilẹ̀ Ejibiti já. Níbi tí a ti gbọ́ èdè tí kò yé wa.
Anumzamo'ma Isipi vahe'ma ha'ma renenteno'a, Josefe naga'mozama avaririsaza trake huno retro hunte'ne. Nagra ontahi'noa agerupinti agerura runo anage hu'ne,
6 Ó wí pé, “Mo gbé àjàgà kúrò ní èjìká yín, a tú ọwọ́ wọn sílẹ̀ kúrò nínú apẹ̀rẹ̀.
Nagra zamafunte'ma me'nea knazana eri atroe. Kna zama e'neriza ekaeka kutamia tamazampintira eri atre'noe.
7 Nínú ìnilára ni ẹ pè mo sì gbà yín là, mo dá a yín lóhùn nínú ìkọ̀kọ̀ àrá, mo dán an yín wò ní odò Meriba. (Sela)
Knafima mani'neta krafa nehazagena, tamagu'vazi'noe. Nagra hanintiri hampompinti monagema hiaza hu'na kenonatamia huramante'noe. Meriba tinte tamamentintia reramahe'na tamage'noe.
8 “Gbọ́, ẹ̀yin ènìyàn mi, èmi ó sì kìlọ̀ fún un yín, bí ìwọ bá fetí sí mi, ìwọ Israẹli.
Tamavumro tamantena tamazeri fatgo hunaku huanki, vahe'nimota antahiho! Israeli vahe'mota tamavumro'ma nentenugeta kea osu mani'neta amne tamagesa antahiho.
9 Ẹ̀yin kì yóò ní Ọlọ́run ilẹ̀ mìíràn láàrín yín; ẹ̀yin kì yóò foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run àjèjì.
Ru vahe'mokizmi anumzantera monora huontege, havi anumzantera tamarena reta monora huonteho.
10 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, ẹni tí ó mú un yín jáde láti Ejibiti. Ẹ la ẹnu yín gbòòrò, èmi yóò sì kún un.
Nagra Ra Anumzana tamagri Anumzamo'na Isipi mopafintira tamagura vazi'na tamavre'na emareri'noa Anumza mani'noe. Tamagira eri aka hunenke'na knare zantaminura tamagipina ante vita'neno.
11 “Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi kì yóò gbọ́ tèmi; Israẹli kò ní tẹríba fún mi.
Hianagi nagri vahe'mo'za keni'a nontahi'za, namagera onte'naze.
12 Nítorí náà ni mo ṣe fi wọ́n fún ọkàn líle wọn láti máa rìn ní ọ̀nà ẹ̀tàn wọn.
Zamagu'amo'ma hanavetige'na zamatroge'za zamagra zamavesi avariri'za vu'naze.
13 “Bí àwọn ènìyàn mi yóò bá gbọ́ tèmi bí Israẹli yóò bá tẹ̀lé ọ̀nà mi,
Tamagra nagri vahe'mota keni'a nentahinkeno, Israeli vahe'mota nagri kante'ma navaririta vanageno'a knare hugahie.
14 ní kánkán ni èmi yóò ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá wọn kí n sì yí ọwọ́ mi padà sí ọ̀tá wọn!
Nagra ame hu'na tamagri ha' vahera zamahe rava hugahue. Ha'ma renezmantaza vahera nazana rusute'na hara huzmagateregahue.
15 Àwọn tí ó kórìíra Olúwa yóò tẹríba níwájú rẹ̀. Ìjìyà wọn yóò sì pẹ́ títí láé.
Ra Anumzamofoma zamavaresrama hunentaza vahe'mo'za agri avurera antri nehu'za tatapa hugahaze. Ana knazana eri vava hu'za vugahaze.
16 Ṣùgbọ́n a ó fi ọkà tí ó dára bọ́ ọ yín èmi ó tẹ́ ẹ yín lọ́rùn pẹ̀lú oyin inú àpáta.”
Hianagi knare zantfama hu'nea witi tami'nena negahaze. Ana nehu'na havefinti afi tumeri taminena neramu hugahaze.