< Psalms 81 >

1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti gittiti. Ti Asafu. Kọrin sókè sí Ọlọ́run agbára wa ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọ́run Jakọbu!
Kathutkung: Asaph Maimae thaonae Cathut koe kacaipounglah la sak awh. Jakop Cathut koe konawm laihoi hram awh.
2 Ẹ mú orin mímọ́, kí ẹ sì mú ìlù wá, tẹ dùùrù dídùn pẹ̀lú ohun èlò orin mímọ́.
La sak awh nateh cecak hah khawng awh. A lawk kahawi e ratoung tamawi hah kueng awh.
3 Ẹ fún ìpè ní oṣù tuntun àní nígbà tí a yàn; ní ọjọ́ àjọ wa tí ó ní ìrònú.
Thapa rei hnin, kamhluem hnin, pawi hnin vah mongka ueng awh.
4 Èyí ni àṣẹ fún Israẹli, àti òfin Ọlọ́run Jakọbu.
Bangkongtetpawiteh, hethateh, Isarelnaw hanlah phunglam lah ao teh, Jakop Cathut kâlawk lah ao.
5 Ó fi múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà fún Josẹfu nígbà tí ó la ilẹ̀ Ejibiti já. Níbi tí a ti gbọ́ èdè tí kò yé wa.
Hethateh, Izip ram pueng a cei awh teh, thai panuek hoeh e lawk thainae hmuen koevah, lawkpanuesaknae Joseph koe a sak e doeh.
6 Ó wí pé, “Mo gbé àjàgà kúrò ní èjìká yín, a tú ọwọ́ wọn sílẹ̀ kúrò nínú apẹ̀rẹ̀.
A loung dawk a hrawm e hnori hah a puen pouh teh, a kut hoi a tawm e a bawm hah a kuem pouh.
7 Nínú ìnilára ni ẹ pè mo sì gbà yín là, mo dá a yín lóhùn nínú ìkọ̀kọ̀ àrá, mo dán an yín wò ní odò Meriba. (Sela)
Rucat navah na kaw teh na rungngang awh. khoparitnae hmuen koehoi na pato awh teh, Meribah tui koehoi na tanouk awh. (Selah)
8 “Gbọ́, ẹ̀yin ènìyàn mi, èmi ó sì kìlọ̀ fún un yín, bí ìwọ bá fetí sí mi, ìwọ Israẹli.
Oe ka taminaw thai awh haw, lawk na thui vai. Oe Isarel ka lawk tarawi awh haw.
9 Ẹ̀yin kì yóò ní Ọlọ́run ilẹ̀ mìíràn láàrín yín; ẹ̀yin kì yóò foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run àjèjì.
Miphun louk cathut nangmouh koe awm mahoeh. Miphun louk cathut na bawk awh mahoeh.
10 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, ẹni tí ó mú un yín jáde láti Ejibiti. Ẹ la ẹnu yín gbòòrò, èmi yóò sì kún un.
Kai teh Cathut Jehovah, Izip ram hoi na kahrawikung doeh. Ka kaw lah na pahni ang awh nateh, ka kawi sak han.
11 “Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi kì yóò gbọ́ tèmi; Israẹli kò ní tẹríba fún mi.
Hatei, ka taminaw ni ka lawk hah ngai awh hoeh. Isarelnaw ni banglahai na pouk awh hoeh.
12 Nítorí náà ni mo ṣe fi wọ́n fún ọkàn líle wọn láti máa rìn ní ọ̀nà ẹ̀tàn wọn.
Amamae lungpatanae koe ka poe teh, amamouh ngai patetlah ao awh.
13 “Bí àwọn ènìyàn mi yóò bá gbọ́ tèmi bí Israẹli yóò bá tẹ̀lé ọ̀nà mi,
Oe ka taminaw ni ka lawk hah ngai boilah, Isarel ni ka lamthung dawn haw pawiteh khe.
14 ní kánkán ni èmi yóò ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá wọn kí n sì yí ọwọ́ mi padà sí ọ̀tá wọn!
A taran tang ka tâ pouh vaiteh, ahnimouh katarankungnaw koe ka kut ka dâw pouh han eite.
15 Àwọn tí ó kórìíra Olúwa yóò tẹríba níwájú rẹ̀. Ìjìyà wọn yóò sì pẹ́ títí láé.
BAWIPA kahmuhmanaw ni a hmalah kâhet awh vaiteh, ka taminaw teh pou a kangning awh han eite.
16 Ṣùgbọ́n a ó fi ọkà tí ó dára bọ́ ọ yín èmi ó tẹ́ ẹ yín lọ́rùn pẹ̀lú oyin inú àpáta.”
Kahawi poung e tavai hoi ka kawk vaiteh, lungsong thung e khoitui hoi a lungkhuekti sak han eite.

< Psalms 81 >