< Psalms 8 >
1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti gittiti. Saamu ti Dafidi. Olúwa, Olúwa wa, orúkọ rẹ̀ ti ní ìyìn tó ní gbogbo ayé! Ìwọ ti gbé ògo rẹ ga ju àwọn ọ̀run lọ.
Thaburi ya Daudi Wee Jehova, o Wee Mwathani witũ, kaĩ rĩĩtwa rĩaku nĩ inene gũkũ thĩ yothe-ĩ! Nĩũigĩte riiri waku o igũrũ matu-inĩ.
2 Láti ẹnu ọmọ ọwọ́ àti ọmọ ọmú ni o ti yan ìyìn nítorí àwọn ọ̀tá rẹ, láti pa àwọn ọ̀tá àti àwọn olùgbẹ̀san lẹ́nu mọ́.
Nĩũtũmĩte rũgooco ruume tũnua-inĩ twa ciana na twa ngenge, nĩ tondũ wa thũ ciaku, nĩguo ũkirie ũrĩa ũrĩ muku nawe o na mwĩrĩhĩria.
3 Nígbà tí mo ro ọ̀run rẹ, iṣẹ́ ìka rẹ, òṣùpá àti ìràwọ̀, tí ìwọ tí gbé kalẹ̀,
Rĩrĩa ndecũũrania ũhoro ũkoniĩ igũrũ rĩu rĩaku, ngoona wĩra wa ciara ciaku, mweri na njata icio wĩkĩrĩte kuo-rĩ,
4 kí ni ènìyàn tí ìwọ ń rò nípa rẹ̀, àní ọmọ ènìyàn tí ìwọ ń ṣe ìtọ́jú rẹ̀?
mũndũ akĩrĩ kĩ tondũ ũikaraga ũkĩmwĩciiragia, nake mũrũ wa mũndũ akĩrĩ kĩ atĩ nĩkĩo ũmũmenyagĩrĩra?
5 Ìwọ ṣe é ní onírẹ̀lẹ̀ díẹ̀ ju Ọlọ́run lọ, ìwọ sì dé e ní adé ògo àti ọlá.
Watũmire atigie o hanini aiganane nawe, na ũkĩmũhumba thũmbĩ ya riiri o na gĩtĩĩo.
6 Ìwọ mú un jẹ ọba lórí gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ rẹ; ìwọ sì fi ohun gbogbo sí abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀:
Wamũtuire wa gwathaga mawĩra ma moko maku; ũkĩiga indo ciothe rungu rwa makinya make:
7 àwọn agbo àgùntàn àti àwọn màlúù, àti ẹranko igbó,
ndũũru ciothe cia mbũri na cia ngʼombe, na nyamũ cia gĩthaka,
8 ẹyẹ ojú ọrun, àti ẹja inú Òkun, àti ohun tí ń wẹ nínú ipa Òkun.
na nyoni cia rĩera-inĩ, na thamaki cia iria-inĩ, na kĩrĩa gĩothe kĩgeragĩra kũu iria-inĩ thĩinĩ.
9 Olúwa, Olúwa wa, orúkọ rẹ ti ní ìyìn tó ní gbogbo ayé!
Wee Jehova, o Wee Mwathani witũ, kaĩ rĩĩtwa rĩaku nĩ inene gũkũ thĩ yothe-ĩ!