< Psalms 8 >
1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti gittiti. Saamu ti Dafidi. Olúwa, Olúwa wa, orúkọ rẹ̀ ti ní ìyìn tó ní gbogbo ayé! Ìwọ ti gbé ògo rẹ ga ju àwọn ọ̀run lọ.
Gittith rhotoeng dongah aka mawt ham David kah tingtoenglung Kaimih kah boeipa Yahweh tah, diklai pum ah na ming metlam a khuet tih, na mueithennah te vaan dongla na khueh mai.
2 Láti ẹnu ọmọ ọwọ́ àti ọmọ ọmú ni o ti yan ìyìn nítorí àwọn ọ̀tá rẹ, láti pa àwọn ọ̀tá àti àwọn olùgbẹ̀san lẹ́nu mọ́.
Nang aka daengdaeh kongah, thunkha neh phuloh te kangkuen sak ham camoe neh cahni ka lamkah sarhi na cuen sak.
3 Nígbà tí mo ro ọ̀run rẹ, iṣẹ́ ìka rẹ, òṣùpá àti ìràwọ̀, tí ìwọ tí gbé kalẹ̀,
Vaan kah na kutngo hla neh aisi boeih na khueh te ka hmuh vaengah,
4 kí ni ènìyàn tí ìwọ ń rò nípa rẹ̀, àní ọmọ ènìyàn tí ìwọ ń ṣe ìtọ́jú rẹ̀?
Balae tih hlanghing te na ngaidam tih, hlang capa te na hip?
5 Ìwọ ṣe é ní onírẹ̀lẹ̀ díẹ̀ ju Ọlọ́run lọ, ìwọ sì dé e ní adé ògo àti ọlá.
Tedae anih te Pathen lakah vel na toem sak phoeiah ni, anih te thangpomnah neh, rhuepomnah na khuem sak.
6 Ìwọ mú un jẹ ọba lórí gbogbo iṣẹ́ ọwọ́ rẹ; ìwọ sì fi ohun gbogbo sí abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀:
Na kutngo te anih na taemrhai sak tih, a kho hmuiah,
7 àwọn agbo àgùntàn àti àwọn màlúù, àti ẹranko igbó,
tu neh saelhung boeih khaw, kohong kah rhamsa khaw,
8 ẹyẹ ojú ọrun, àti ẹja inú Òkun, àti ohun tí ń wẹ nínú ipa Òkun.
vaan kah vaa neh tuitunli kongtlang kah aka kat tuitunli nga khaw boeih a khueh pah.
9 Olúwa, Olúwa wa, orúkọ rẹ ti ní ìyìn tó ní gbogbo ayé!
Aw BOEIPA, kaimih kah boeipa tah na ming khaw diklai pum ah khuet tangkik.