< Psalms 78 >
1 Maskili ti Asafu. Ẹ̀yin ènìyàn mi, ẹ gbọ́ ẹ̀kọ́ mi; tẹ́tí rẹ sí ọ̀rọ̀ ẹnu mi.
Asaf yazƣan «Masⱪil»: — I Mening hǝlⱪim, tǝlimimni anglanglar, Aƣzimdiki sɵzlǝrgǝ ⱪulaⱪ selinglar.
2 Èmi ó la ẹnu mi ní òwe, èmi o sọ ohun ìkọ̀kọ̀, ohun ti ọjọ́ pípẹ́;
Mǝn aƣzimni bir tǝmsil bilǝn aqimǝn, Ⱪǝdimki tepixmaⱪlarni elan ⱪilimǝn.
3 ohun tí a ti gbọ́ tí a sì ti mọ̀, ohun tí àwọn baba wa ti sọ fún wa.
Biz bularni angliƣan, bilgǝn, Ata-bowilirimiz ularni bizgǝ eytip bǝrgǝn.
4 Àwa kì yóò pa wọ́n mọ́ kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọmọ, ní fífi ìyìn Olúwa, àti ipa rẹ̀ àti iṣẹ́ ìyanu tó ti ṣe hàn fún ìran tí ń bọ̀.
Biz bularni ularning ǝwladliridin yoxurmaymiz, Kelidiƣan dǝwrgǝ Pǝrwǝrdigarning mǝdⱨiyilirini, Uning küq-ⱪudritini, Uning ⱪilƣan karamǝt ixlirini bayan ⱪilimiz.
5 Ó gbé ẹ̀rí kalẹ̀ ní Jakọbu o sì fìdí àṣẹ múlẹ̀ ní Israẹli, èyí tí ó pàṣẹ fún àwọn baba ńlá wa láti kọ́ àwọn ọmọ wọn,
Qünki U Yaⱪupta bir agaⱨ-guwaⱨni bekitkǝn, Israilda bir ⱪanunni ornatⱪan; U ata-bowilirimizƣa bularni ɵz pǝrzǝntlirigǝ ɵgitixni buyruƣan;
6 nítorí náà, àwọn ìran tí ń bọ̀ yóò mọ̀ wọ́n bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ tí a kò tí ì bí tí yóò dìde tí wọn yóò sọ fún àwọn ọmọ wọn.
Xundaⱪ ⱪilip kelǝr dǝwr, Yǝni tuƣulidiƣan balilarmu bularni bilsun, Ularmu ornidin turup ɵz baliliriƣa bularni ɵgǝtsun;
7 Nígbà náà ni wọ́n ò fi ìgbẹ́kẹ̀lé wọn sínú Ọlọ́run wọn kò sì ní gbàgbé iṣẹ́ Ọlọ́run ṣùgbọ́n wọn ó pa àṣẹ rẹ̀ mọ́.
Pǝrzǝntliri ümidini Hudaƣa baƣlisun, Tǝngrining ⱪilƣanlirini untumisun, Bǝlki Uning ǝmrlirigǝ kirsun;
8 Kí wọn kí ó má ṣe dàbí àwọn baba ńlá wọn, ìran alágídí àti ọlọ́tẹ̀, ìran tí ọkàn wọn kò ṣọ òtítọ́ si olóore, àti ẹ̀mí ẹni tí kò bá Ọlọ́run dúró ṣinṣin.
Ular ata-bowiliriƣa ohximisun dǝp, Yǝni jaⱨil ⱨǝm asiy bir dǝwr, Ɵz ⱪǝlbini durus ⱪilmiƣan, Roⱨi Tǝngrigǝ wapaliⱪta turmiƣan bir dǝwrgǝ ohximisun dǝp, U xundaⱪ [buyruƣandur].
9 Àwọn ọkùnrin Efraimu, tí ó há mọ́ ọ tí wọ́n mú ọrun, wọ́n yípadà ní ọjọ́ ogun
Mana Əfraimning ǝwladliri, Ⱪorallanƣan oⱪyaqilar bolsimu, Jǝng künidǝ sǝptin yandi.
10 Wọn kò pa májẹ̀mú Ọlọ́run mọ́ wọn sì kọ̀ láti máa gbé nínú òfin rẹ̀.
Ular Hudaning ǝⱨdisini tutmidi, Bǝlki Uning Tǝwrat-ⱪanunida mengixni rǝt ⱪildi.
11 Wọ́n gbàgbé ohun tí ó ti ṣe, àwọn ìyanu tí ó ti fihàn wọ́n.
Ular Uning ⱪilƣanlirini, Ɵzlirigǝ kɵrsǝtkǝn karamǝtlirini untudi.
12 Ó ṣe ìyanu níwájú àwọn baba wọn ní ilẹ̀ Ejibiti, ní agbègbè Ṣoani.
U Misirning zeminida, Zoanning dalasida, Ularning ata-bowilirining kɵz aldida mɵjizilǝrni kɵrsǝtkǝnidi;
13 Ó pín òkun ní yà, ó sì mú wọn kọjá Ó mù kí omi náà dúró bi odi gíga.
U dengizni bɵlüwetip, Ularni otturisidin ɵtküzgǝn; Sularni dɵwǝ-dɵwǝ ⱪilip tiklidi.
14 Ní ọ̀sán, ó fi ìkùùkuu àwọsánmọ̀ ṣe amọ̀nà wọn àti ní gbogbo òru pẹ̀lú ìmọ́lẹ̀ iná.
U kündüzdǝ bulut bilǝn, Keqidǝ ot nuri bilǝn ularni yetǝklidi.
15 Ó sán àpáta ní aginjù ó sì fún wọn ní omi mímu lọ́pọ̀lọ́pọ̀ bí ẹni pé láti inú ibú wá.
Qɵl-bayawanda taxlarni yeriwǝtti, Qongⱪur surlardin urƣup qiⱪⱪandǝk iqimlikni mol ⱪildi;
16 Ó mú ìṣàn omi jáde láti inú àpáta omi ṣíṣàn sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí odò.
U hada taxtin ɵstǝng-eⱪinlarni ⱨasil ⱪildi, Suni dǝryalardǝk aⱪⱪuzdi.
17 Wọ́n sì tún tẹ̀síwájú láti dẹ́ṣẹ̀ sí i ní ìṣọ̀tẹ̀ sí Ọ̀gá-ògo ní aginjù.
Biraⱪ ular yǝnǝ Uning aldida gunaⱨ ⱪiliwǝrdi, Qɵldǝ Ⱨǝmmidin Aliy Bolƣuqiƣa asiyliⱪ ⱪildi.
18 Wọ́n mọ̀ ọ́n mọ̀ dán Ọlọ́run wò nípa bíbéèrè fún oúnjẹ tí wọn bẹ̀bẹ̀ fún.
Ular kɵnglidǝ Tǝngrini sinidi, Nǝpsini ⱪanduruxⱪa yemǝklikni tǝlǝp ⱪildi.
19 Wọ́n sọ̀rọ̀-òdì sí Ọlọ́run, wí pé “Ọlọ́run ha lè tẹ́ tábìlì ní aginjù?
Ular Hudani ⱨaⱪarǝtlǝp: — «Tǝngri qɵl-dǝxttǝ dastihan salalamdu?
20 Nígbà tí ó lu àpáta, omi tú jáde, odò sì sàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀ ṣùgbọ́n òun ha lè fún wa lóúnjẹ ó ha le pèsè ẹran fún àwọn ènìyàn rẹ̀?”
Mana U ⱪoram taxni uruwidi, Sular urƣup, Eⱪinlar bulaⱪtǝk texip qiⱪti; Əmdi U bizgǝ nanmu berǝlǝmdu? Ɵz hǝlⱪini gɵx bilǝn tǝminliyǝlǝmdu?» — deyixti.
21 Nígbà tí Olúwa gbọ́ wọn, ó bínú gidigidi; iná rẹ̀ sọ̀kalẹ̀ sí Jakọbu, ìbínú rẹ̀ sì rú sí Israẹli,
Xuning bilǝn Pǝrwǝrdigar anglap, ƣǝzǝplǝndi; Yaⱪupⱪa ot tutaxti, Israilƣa aqqiⱪi kɵtürüldi;
22 nítorí wọn kò gba Ọlọ́run gbọ́, wọn kò sì gbẹ́kẹ̀lé ìgbàlà rẹ̀.
Qünki ular Hudaƣa ixǝnmidi, Uning nijatliⱪiƣa ular tayanmidi,
23 Síbẹ̀ ó pàṣẹ fún ìràwọ̀ ojú ọ̀run, ó sì ṣí ìlẹ̀kùn ọ̀run sílẹ̀;
U ǝrxtin bulutlarni buyrup, Asman dǝrwazilirini aqⱪanidi;
24 Ó rọ manna fún àwọn ènìyàn láti jẹ, ó fún wọn ní ọkà láti ọ̀run.
U ular üstigǝ «manna»ni yaƣdurup, Ularƣa ǝrxtiki axliⱪni bǝrgǝnidi;
25 Àwọn ènìyàn jẹ oúnjẹ àwọn angẹli; Ó fún wọn ní oúnjẹ ní àjẹyó,
Xuning bilǝn insanlar küq igilirining nenini yegǝnidi; U ularƣa ⱪanƣuqǝ ozuⱪni ǝwǝtkǝnidi.
26 Ó mú afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn láti ọ̀run wá ó mú afẹ́fẹ́ gúúsù wá nípa agbára rẹ̀.
Əmdi U asmanda xǝrⱪ xamili qiⱪirip, Küqi bilǝn jǝnub xamilinimu elip kǝldi;
27 Ó rọ òjò ẹran sílẹ̀ sórí wọn bí erùpẹ̀ ilẹ̀, àti ẹyẹ abìyẹ́ gẹ́gẹ́ bí iyanrìn etí òkun
U gɵxni qang-tozandǝk ular üstigǝ qüxürdi, Dengizlar saⱨilidiki ⱪumlardǝk uqar-ⱪanatlarni yaƣdurdi.
28 Ó jẹ́ kí wọn jáde ní ibùdó wọn, yíká àgọ́ wọn.
U bularni ularning bargaⱨining otturisiƣa, Qedirlirining ǝtrapiƣa qüxürdi.
29 Wọ́n jẹ, wọ́n sì yó jọjọ nítorí ó ti fún wọn ní ohun tí wọn fìtara bẹ̀bẹ̀ fún.
Ular boluxiqǝ yǝp toyuxti, Qünki ularning nǝpsi tartⱪinini [Huda] ularƣa kǝltürgǝnidi.
30 Ṣùgbọ́n wọn kò kúrò nínú oúnjẹ tí wọn fìtara bẹ̀bẹ̀ fún, nígbà tí oúnjẹ wọn sì wà ní ẹnu wọn,
Lekin ular nǝpsi tartⱪinidin tehi zerikmǝyla, Gɵxni eƣizlirida tehi qaynawatⱪinidila,
31 ìbínú Ọlọ́run dìde sí wọn ó pa àwọn tí ó jùlọ nínú wọn, ó sì lu àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin Israẹli bolẹ̀.
Hudaning ƣǝzipi ularƣa ⱪarita ⱪozƣaldi; U ulardin ǝng ⱪamǝtliklirini ⱪiriwǝtti, Israilning sǝrhil yaxlirini yǝrgǝ uruwǝtti.
32 Nínú gbogbo ìwọ̀nyí, wọ́n ń dẹ́ṣẹ̀ síwájú; nínú gbogbo iṣẹ́ ìyanu rẹ̀, wọ́n kò gbàgbọ́.
Mana, xundaⱪ bolsimu, Ular yǝnila dawamliⱪ gunaⱨ ⱪiliwǝrdi, Uning mɵjizilirigǝ tehiqila ixǝnmidi;
33 O fi òpin sí ayé wọn nínú asán àti ọdún wọn nínú ìpayà.
Xunga U ularning künlirini biⱨudiliktǝ, Yillirini dǝkkǝ-dükkilik iqidǝ tügǝtküzdi.
34 Nígbàkígbà tí Ọlọ́run bá pa wọ́n, wọn yóò wá a kiri; wọn yóò fi ìtara yípadà sí i.
U ularni ɵltürgili turƣanda, Andin ular Uni izdidi; Ular yolidin yenip, intilip Tǝngrini izdidi;
35 Wọ́n rántí pé Ọlọ́run ní àpáta wọn; wí pé Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo jùlọ ni olùràpadà àpáta wọn.
Ular Hudaning ularning uyultexi ikǝnlikini, Ⱨǝmmidin Aliy Bolƣuqi Tǝngrining ularning ⱨǝmjǝmǝt-ⱪutⱪuzƣuqisi ikǝnlikini esigǝ kǝltürdi.
36 Ṣùgbọ́n nígbà náà ni wọ́n yóò pọ́n ọn pẹ̀lú ẹnu wọ́n wọ́n fi ahọ́n wọ́n purọ́ fún un;
Biraⱪ ular aƣzi bilǝn Uningƣa huxamǝt ⱪildi, Tili bilǝn Uningƣa yalƣan sɵz ⱪildi;
37 ọkàn wọn kò sòtítọ́ sí i, wọn kò jẹ́ olódodo sí májẹ̀mú rẹ̀.
Qünki ularning kɵngli Uningƣa sadiⱪ bolmidi, Ular Uning ǝⱨdisini qing tutmidi.
38 Síbẹ̀ ó ṣàánú; ó dárí àìṣedéédéé wọn jì òun kò sì pa wọ́n run nígbà púpọ̀ ló ń yí ìbínú rẹ̀ padà kò sì ru ìbínú rẹ̀ sókè
Biraⱪ U yǝnila rǝⱨimdil idi; Ⱪǝbiⱨlikini kǝqürüp, ularni yoⱪatmidi; U ⱪayta-ⱪayta Ɵz ƣǝzipidin yandi, U ⱪǝⱨrini ⱪozƣiƣini bilǝn ⱨǝmmini tɵkmidi.
39 Ó rántí pé ẹlẹ́ran ara ni wọ́n, afẹ́fẹ́ tó ń kọjá tí kò lè padà.
U ularning pǝⱪǝt ǝt igiliri, Kǝtsǝ ⱪaytip kǝlmǝs bir nǝpǝs ikǝnlikini yad ǝtti.
40 Nígbà gbogbo ní wọn ń ṣọ̀tẹ̀ sí i ní aginjù wọn mú un bínú nínú ilẹ̀ tí ó di ahoro!
Ular qɵl-dǝxttǝ xunqǝ kɵp ⱪetim Uning aqqiⱪini kǝltürdi. Xunqǝ kɵp ⱪetim bayawanda kɵngligǝ azar bǝrdi!
41 Síwájú àti síwájú wọ́n dán Ọlọ́run wò; wọ́n mú ẹni mímọ́ Israẹli bínú.
Bǝrⱨǝⱪ, ular ⱪaytidin yoldin qǝtnǝp Tǝngrini sinidi, Israildiki Muⱪǝddǝs Bolƣuqining yürikini zedǝ ⱪildi.
42 Wọ́n kò rántí agbára rẹ̀: ní ọjọ́ tí ó rà wọ́n padà lọ́wọ́ àwọn aninilára,
Ular Uning ⱪolini [ǝslimidi]; Ularni zomigǝrning qanggilidin ⱨɵrlükkǝ ⱪutⱪuzƣan künini, Ⱪandaⱪ ⱪilip Misirda karamǝtlǝrni yaritip, Zoan dalasida mɵjizilǝrni kɵrsǝtkinini esidin qiⱪardi.
43 ní ọjọ́ tí ó fi iṣẹ́ ìyanu rẹ̀ hàn ní Ejibiti, àti iṣẹ́ àmì rẹ̀ ni ẹkùn Ṣoani
44 Ó sọ omi wọn di ẹ̀jẹ̀; wọn kò lè mu láti odò wọn.
U [Misirliⱪlarning] dǝryalirini, eⱪinlirini ⱪanƣa aylandurup, Ularni iqǝlmǝs ⱪilip ⱪoydi;
45 Ó rán ọ̀wọ́ eṣinṣin láti pa wọ́n run, àti ọ̀pọ̀lọ́ tí ó bá wọn jẹun.
Ularning arisiƣa nǝxtǝrlik qiwinlarni top-topi bilǝn ǝwǝtti, Ⱨalak ⱪilar paⱪilarni mangdurdi;
46 Ó fi ọkà wọn fún láńtata, àwọn ìre oko wọn fún eṣú.
Ularning ziraǝtlirini kepinǝk ⱪurtliriƣa tutup berip, Mǝⱨsulatlirini qekǝtkilǝrgǝ bǝrdi;
47 Ó fi yìnyín ba àjàrà wọn jẹ́ ó bá èso sikamore wọn jẹ́.
Üzüm tallirini mɵldür bilǝn urdurup, Ənjürlirini ⱪiraw bilǝn üxxütiwǝtti.
48 Ó fi ohun ọ̀sìn wọn fún yìnyín, agbo ẹran wọn fún mọ̀nàmọ́ná.
U kalilirini mɵldürgǝ soⱪturup, Mallirini qaⱪmaⱪ otlirida [kɵydüriwǝtti].
49 Ó mú kíkorò ìbínú rẹ̀ wá sí wọn lára, ìrunú àti ìkáàánú, àti ìpọ́njú, nípa rírán angẹli apanirun sí wọn.
U ularƣa ƣǝzipining dǝⱨxǝtlikini — Ⱪǝⱨrini, aqqiⱪini ⱨǝm eƣir külpǝtlǝrni, Balayi’apǝt elip kelidiƣan bir türküm pǝrixtilǝrnimu qüxürdi.
50 Ó pèsè ipa fún ìbínú rẹ̀, òun kò gbà wọ́n lọ́wọ́ ikú, ṣùgbọ́n ó fi ẹ̀mí wọ́n fún àjàkálẹ̀-ààrùn.
U Ɵz ƣǝzipi üqün bir yolni tüzlǝp ⱪoydi; Ularning jenini ɵlümdin ayimay, Bǝlki ⱨayatini wabaƣa tapxurdi;
51 Ó kọlu àwọn àkọ́bí ọmọ ọkùnrin Ejibiti, olórí agbára wọn nínú àgọ́ Hamu.
U Misirda barliⱪ tunji tuƣulƣan balilarni, Ⱨamning qedirlirida ularning ƣururi bolƣan tunji oƣul balilirini ⱪiriwǝtti.
52 Ṣùgbọ́n ó mú àwọn ènìyàn rẹ̀ jáde bí ọ̀wọ́ ẹran; ó ṣọ́ wọn gẹ́gẹ́ bí àgùntàn nínú aginjù.
U padiqidǝk Ɵz hǝlⱪini Misirdin sǝpǝrgǝ atlandurup, Qɵl-bayawandin ularni ⱪoy padisidǝk baxlap mangdi;
53 Ó dáàbò bò wọ́n dáradára, nítorí náà ni ẹ̀rù kò ṣe bà wọ́n ṣùgbọ́n òkun padé mọ́ àwọn ọ̀tá wọn.
Ularni aman-esǝn yetǝkligǝqkǝ, Ular ⱪorⱪunqtin haliy bolup mangdi; Düxmǝnlirini bolsa, dengiz yutup kǝtti.
54 Bákan náà ni ó mú wọn wá sí etí ilẹ̀ mímọ́ rẹ̀ òkè tí ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ ti gbà
U ularni Ɵz muⱪǝddǝs zeminining qegrasiƣa, Ong ⱪoli igiliwalƣan bu taƣliⱪⱪa elip kǝldi.
55 Ó lé kèfèrí jáde níwájú wọn ó sì fi títa okùn pín ilẹ̀ náà fún wọn gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ ìní; ó mú àwọn ẹ̀yà Israẹli jókòó ní ilẹ̀ wọn.
U ǝllǝrni ularning aldidin ⱪoƣliwetip, Zemin üstigǝ tana tartⱪuzup ɵlqǝp, ularƣa tǝⱪsim ⱪildi; Israil ⱪǝbililirini ularning qedirliriƣa olturaⱪlaxturdi.
56 Ṣùgbọ́n wọn dán Ọlọ́run wò wọn sì ṣọ̀tẹ̀ sí Ọ̀gá-ògo; wọn kò pa àṣẹ rẹ̀ mọ́.
Biraⱪ ular Hudani, Ⱨǝmmidin Aliy Bolƣuqini sinap aqqiⱪlandurdi, Uning tapxurƣan guwaⱨ-agaⱨlirini tutmidi;
57 Ṣùgbọ́n wọ́n yípadà, wọn jẹ́ aláìṣòdodo gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn wọ́n sì pẹ̀yìndà sí apákan bí ọrun ẹ̀tàn.
Bǝlki ata-bowliridǝk yoldin teyip asiyliⱪ ⱪildi, Hain oⱪyadǝk ⱪeyip kǝtti.
58 Wọ́n bí i nínú pẹ̀lú ibi gíga wọn; wọn rú owú rẹ̀ sókè nípa òrìṣà wọn.
Ular egizliktǝ ⱪurƣan ibadǝtgaⱨlar bilǝn Uning ƣǝzipini ⱪozƣidi, Oyma butliri bilǝn Uning yürikini ɵrtidi.
59 Nígbà tí Ọlọ́run gbọ́ wọn, inú bí i gidigidi; ó kọ Israẹli pátápátá.
Huda ularni anglap ƣǝzǝplǝndi, Israildin intayin yirgǝndi.
60 Ó kọ àgọ́ Ṣilo sílẹ̀, àgọ́ tí ó ti gbé kalẹ̀ láàrín àwọn ènìyàn.
U Xiloⱨdiki makanini, Yǝni U insan arisida turƣan qedirni taxlap kǝtti,
61 Ó rán àpótí ẹ̀rí, agbára rẹ̀ lọ sí ìgbèkùn, dídán ògo rẹ̀ lọ sí ọwọ́ àwọn ọ̀tá.
Ɵzining ⱪudrǝt bǝlgisini bulap ketixkǝ, Xan-xǝripini ixƣaliyǝtqilǝrning ⱪoliƣa bǝrdi;
62 Ó fi àwọn ènìyàn rẹ̀ lé idà lọ́wọ́, ó sì bínú sí àwọn ohun ìní rẹ̀.
Ɵz hǝlⱪini ⱪiliqⱪa tapxurdi, Ɵzining mirasi bolƣanlardin intayin ƣǝzǝplǝndi.
63 Iná run àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin wọn, àwọn ọmọbìnrin wọn kò sì ní orin ìgbéyàwó:
Ot ularning yigitlirini yalmidi, Ⱪizliri toy nahxilirida mahtalmaytti.
64 àfi àlùfáà wọn fún idà, àwọn opó wọn kò sì le è sọkún.
Ularning kaⱨinliri ⱪiliq astida yiⱪildi, Lekin tul hotunliri ⱨaza tutmidi.
65 Olúwa sì jí gẹ́gẹ́ bí ẹni ojú oorun, gẹ́gẹ́ bí ọkùnrin ti i jí kúrò nínú ìraníyè ọtí.
Andin Rǝb birsi uyⱪudin oyƣandǝk oyƣandi, Xarabtin jasarǝtlǝngǝn palwandǝk towlidi.
66 Ó kọlu àwọn ọ̀tá rẹ̀ padà; ó fi wọn sínú ìtìjú ayérayé.
U rǝⱪiblirini urup qekindürüp, Ularni tügimǝs rǝswaƣa ⱪaldurdi.
67 Nígbà náà ni ó kọ́ àgọ́ Josẹfu, kò sì yan ẹ̀yà Efraimu,
Yüsüpning qedirini xallap, rǝt ⱪildi; Əfraim ⱪǝbilisini tallimidi;
68 ṣùgbọ́n ó yan ẹ̀yà Juda, òkè Sioni, èyí tí ó fẹ́ràn.
Bǝlki Yǝⱨuda ⱪǝbilisini, Yahxi kɵrgǝn Zion teƣini tallidi.
69 Ó kọ́ ibi mímọ́ rẹ̀, ibi gíga, gẹ́gẹ́ bí ayé tí ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ títí láé.
[Xu yǝrdǝ] muⱪǝddǝs jayini taƣ qoⱪⱪiliridǝk, Yǝr-zeminni ǝbǝdiy ornatⱪandǝk mǝzmut bina ⱪildi;
70 Ó yan Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀ ó mú láti inú àwọn agbo ẹran;
U Ɵz ⱪuli Dawutni tallap, Uni ⱪoy ⱪotanliridin qaⱪiriwaldi;
71 Ó mú un jáde nínú ìtọ́jú àgùntàn láti jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn àwọn ènìyàn rẹ̀ Jakọbu àti Israẹli ogún un rẹ̀.
Ⱪozilirini emitidiƣan saƣliⱪlarni ǝgixip beⱪixtin ayrip, Uni Ɵz hǝlⱪi Yaⱪupni, mirasi bolƣan Israilni beⱪixⱪa qiⱪardi.
72 Dafidi sì ṣọ́ wọn pẹ̀lú òtítọ́ inú ọkàn; pẹ̀lú ọwọ́ òye ni ó fi darí wọn.
Dawut ularni ⱪǝlbidiki durusluⱪi bilǝn baⱪti, Ⱪolining ǝpqilliki bilǝn ularni yetǝklidi.