< Psalms 76 >

1 Fún adarí orin. Pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn. Saamu ti Asafu. Orin. Ní Juda ni a mọ Ọlọ́run; orúkọ rẹ̀ sì lágbára ní Israẹli
Neghmichilerning béshigha, tarliq sazlarda chélinsun dep tapshurulghan, Asafning küy-naxshisi: — Yehudada Xuda tonulghandur; Uning nami Israilda ulughdur.
2 Àgọ́ rẹ̀ wà ní Salẹmu, ibùgbé rẹ̀ ni Sioni.
Uning panahiy jayi Salémda, Zion téghida Uning makani bar.
3 Níbẹ̀ ni ó ṣẹ́ ọfà, asà àti àwọn idà, ohun ìjà ogun. (Sela)
U yerde U otluq oqlarni, Qalqan, qilich hem jeng qorallirini chéqip tashlidi. (Sélah)
4 Ìwọ ni ògo àti ọlá, ju òkè ńlá ìkógun wọ̀nyí lọ.
Özüng ow-olja taghliridin neqeder shereplik, neqeder elasen!
5 A kó àwọn alágídí ọkàn ní ìkógun wọ́n sun oorun ìgbẹ̀yìn wọn; kò sí ọ̀kan nínú àwọn akọni tó lè gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè.
Baturlar bulandi; Ular uzun uyqugha ketti; Palwanlarning héchqaysisi öz qolini kötürelmidi.
6 Ní ìfibú rẹ, Ọlọ́run Jakọbu, àwọn ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ ogun sì dùbúlẹ̀ síbẹ̀.
Séning eyiblishing bilen, i Yaqupning Xudasi, Jeng harwisi hem atlar ölüktek uxlitildi.
7 Ìwọ nìkan ni ó yẹ kí a bẹ̀rù. Ta ló lé dúró níwájú rẹ, nígbà tí ìwọ bá ń bínú?
Sendin, Sendin qorqush kérektur; Ghezeplen’giningde kim aldingda turalisun?
8 Ìwọ ń ṣe ìdájọ́ láti ọ̀run, ilé ayé bẹ̀rù, ó sì dúró jẹ́ẹ́,
Yer yüzidiki barliq yawash möminlerni qutquzush üchün, Sen Xuda soraq qilishqa ornungdin turghan waqtingda, Asmandin hökümni chiqirip anglatquzdung; Yer bolsa wehimige chüshüp, süküt qildi. (Sélah)
9 nígbà tí, ìwọ Ọlọ́run, bá dìde láti ṣe ìdájọ́, láti gba àwọn ẹni ìnilára ilẹ̀ náà. (Sela)
10 Lóòótọ́, ìbínú rẹ sí àwọn ènìyàn ń mú ìyìn wá fún ọ, ẹni tí ó yọ nínú ìbínú rẹ ní a dá nígbà tí ìwọ bá fi ìbínú ìyókù di ara rẹ ni àmùrè.
Chünki insanlarning qehri Sanga shöhret keltüridu; Ularning qalghan qehri Sanga belwagh bolidu.
11 Jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ kí o sì mú un ṣẹ; kí gbogbo àwọn tí ó yí i ká mú ẹ̀bùn wá fún ẹni tí ó tọ́ láti bẹ̀rù.
Perwerdigar Xudayinglargha qesem qilip, emel qilinglar; Uning etrapidiki yurttikiler qorqushi kérek bolghuchigha hediyeler sunsun;
12 Ó ké ẹ̀mí àwọn aládé kúrò; àwọn ọba ayé sì ń bẹ̀rù rẹ̀.
U emirlerningmu rohini sunduridu; U yer yüzidiki padishahlargha dehshetliktur.

< Psalms 76 >