< Psalms 76 >

1 Fún adarí orin. Pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn. Saamu ti Asafu. Orin. Ní Juda ni a mọ Ọlọ́run; orúkọ rẹ̀ sì lágbára ní Israẹli
Asafa dziesma, dziedātāju vadonim, dziedama ar koklēm. Dievs ir atzīts iekš Jūda, iekš Israēla viņa vārds ir liels;
2 Àgọ́ rẹ̀ wà ní Salẹmu, ibùgbé rẹ̀ ni Sioni.
Un Salemē ir Viņa telts, un Ciānā Viņa dzīvoklis.
3 Níbẹ̀ ni ó ṣẹ́ ọfà, asà àti àwọn idà, ohun ìjà ogun. (Sela)
Tur Viņš salauza stopa bultas, priekšturamās bruņas un zobenu un karu.(Sela.)
4 Ìwọ ni ògo àti ọlá, ju òkè ńlá ìkógun wọ̀nyí lọ.
Spožs Tu esi un augsts uz kalniem, kur laupījumu sakrāj.
5 A kó àwọn alágídí ọkàn ní ìkógun wọ́n sun oorun ìgbẹ̀yìn wọn; kò sí ọ̀kan nínú àwọn akọni tó lè gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè.
Tie sirds lepnie ir aplaupīti un guļ savā miegā; visiem vareniem ļaudīm rokas nogurušas.
6 Ní ìfibú rẹ, Ọlọ́run Jakọbu, àwọn ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ ogun sì dùbúlẹ̀ síbẹ̀.
No Tavas rāšanās, ak Jēkaba Dievs, nāves miegā nogāzti rati un zirgi.
7 Ìwọ nìkan ni ó yẹ kí a bẹ̀rù. Ta ló lé dúró níwájú rẹ, nígbà tí ìwọ bá ń bínú?
Tu, Tu esi bijājams, un kas Tavā priekšā var pastāvēt Tavas dusmības laikā?
8 Ìwọ ń ṣe ìdájọ́ láti ọ̀run, ilé ayé bẹ̀rù, ó sì dúró jẹ́ẹ́,
No debesīm Tu lieci dzirdēt tiesu, zeme bīstas un top klusa,
9 nígbà tí, ìwọ Ọlọ́run, bá dìde láti ṣe ìdájọ́, láti gba àwọn ẹni ìnilára ilẹ̀ náà. (Sela)
Kad Dievs ceļas uz sodību, palīdzēt visiem bēdīgiem virs zemes. (Sela)
10 Lóòótọ́, ìbínú rẹ sí àwọn ènìyàn ń mú ìyìn wá fún ọ, ẹni tí ó yọ nínú ìbínú rẹ ní a dá nígbà tí ìwọ bá fi ìbínú ìyókù di ara rẹ ni àmùrè.
Kad cilvēki bargojās, tad Tavs gods paaugstinājās, un ar visukarstām dusmām Tu apjozies.
11 Jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ kí o sì mú un ṣẹ; kí gbogbo àwọn tí ó yí i ká mú ẹ̀bùn wá fún ẹni tí ó tọ́ láti bẹ̀rù.
Solāties un maksājiet Tam Kungam, savam Dievam. Visi, kas ap Viņu, lai nes dāvanas Tam bijājamam,
12 Ó ké ẹ̀mí àwọn aládé kúrò; àwọn ọba ayé sì ń bẹ̀rù rẹ̀.
Kas sirdi paņem lieliem kungiem, un ir bijājams pasaules ķēniņiem.

< Psalms 76 >