< Psalms 76 >

1 Fún adarí orin. Pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn. Saamu ti Asafu. Orin. Ní Juda ni a mọ Ọlọ́run; orúkọ rẹ̀ sì lágbára ní Israẹli
Thaburi ya Asafu Kũu Juda Ngai nĩoĩkaine; rĩĩtwa rĩake nĩ inene thĩinĩ wa Isiraeli.
2 Àgọ́ rẹ̀ wà ní Salẹmu, ibùgbé rẹ̀ ni Sioni.
Hema yake ĩrĩ kũu Salemu, gĩikaro gĩake kĩrĩ Zayuni.
3 Níbẹ̀ ni ó ṣẹ́ ọfà, asà àti àwọn idà, ohun ìjà ogun. (Sela)
Kũu nĩkuo oinangĩire mĩguĩ ya ũta ĩkũhenia, akiunanga ngo na hiũ ciao cia njora, o na indo ciao ciothe cia mbaara.
4 Ìwọ ni ògo àti ọlá, ju òkè ńlá ìkógun wọ̀nyí lọ.
Wee ũcangararĩte nĩ ũtheri, ũkagĩa na ũkaru gũkĩra irĩma irĩ na ũtonga wa nyamũ cia iguĩma.
5 A kó àwọn alágídí ọkàn ní ìkógun wọ́n sun oorun ìgbẹ̀yìn wọn; kò sí ọ̀kan nínú àwọn akọni tó lè gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè.
Andũ arĩa njamba magwĩte magatunywo indo, magakoma toro wao wa gĩkuũ; gũtirĩ o na ũmwe wa njamba cia ita ũngĩambararia moko make.
6 Ní ìfibú rẹ, Ọlọ́run Jakọbu, àwọn ẹṣin àti kẹ̀kẹ́ ogun sì dùbúlẹ̀ síbẹ̀.
Nĩ ũndũ wa ikũũma rĩaku, Wee Ngai wa Jakubu, mbarathi o ũndũ ũmwe na ngaari cia ita igwĩte thĩ ikaaga kwĩigua.
7 Ìwọ nìkan ni ó yẹ kí a bẹ̀rù. Ta ló lé dúró níwájú rẹ, nígbà tí ìwọ bá ń bínú?
Wee nowe wa gwĩtigĩrwo. Nũũ ũngĩrũgama mbere yaku rĩrĩa ũrĩ mũrakaru?
8 Ìwọ ń ṣe ìdájọ́ láti ọ̀run, ilé ayé bẹ̀rù, ó sì dúró jẹ́ẹ́,
Wamenyithanirie itua rĩaku ũrĩ o kũu igũrũ, nayo thĩ ĩgĩĩtigĩra na ĩgĩkira ki,
9 nígbà tí, ìwọ Ọlọ́run, bá dìde láti ṣe ìdájọ́, láti gba àwọn ẹni ìnilára ilẹ̀ náà. (Sela)
rĩrĩa Wee Ngai, warũgamire ũtuanĩre ciira, nĩguo ũhonokie arĩa othe anyamaarĩku a bũrũri.
10 Lóòótọ́, ìbínú rẹ sí àwọn ènìyàn ń mú ìyìn wá fún ọ, ẹni tí ó yọ nínú ìbínú rẹ ní a dá nígbà tí ìwọ bá fi ìbínú ìyókù di ara rẹ ni àmùrè.
Ti-itherũ mangʼũrĩ ma andũ nĩmagakũgoocithia, na ũkeyoha matigari ma mangʼũrĩ maku ta mũcibi.
11 Jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa Ọlọ́run rẹ kí o sì mú un ṣẹ; kí gbogbo àwọn tí ó yí i ká mú ẹ̀bùn wá fún ẹni tí ó tọ́ láti bẹ̀rù.
Mwĩhĩtei mĩĩhĩtwa harĩ Jehova Ngai wanyu na mũmĩhingie; rekei mabũrũri marĩa mothe mũriganĩtie namo marehere ũcio wa gwĩtigĩrwo iheo.
12 Ó ké ẹ̀mí àwọn aládé kúrò; àwọn ọba ayé sì ń bẹ̀rù rẹ̀.
Athuthaga roho wa arĩa maathanaga; etigagĩrwo nĩ athamaki a thĩ.

< Psalms 76 >