< Psalms 75 >

1 Fún adarí orin. Tí ohùn, “Má ṣe parun.” Saamu ti Asafu. Orin. A fi ìyìn fún ọ, Ọlọ́run, a yìn ọ́, nítorí orúkọ rẹ súnmọ́ tòsí; àwọn ènìyàn ń sọ ti ìyanu rẹ.
Přednímu z kantorů, jako: Nezahlazuj, žalm Azafův, a píseň. Oslavujeme tě, Bože, oslavujeme; nebo že jest blízké jméno tvé, vypravují to předivní skutkové tvoji.
2 Ìwọ wí pé, “Mo yan àkókò ìyàsọ́tọ̀; Èmi ni ẹni tí ń ṣe ìdájọ́ òdodo.
Když přijde čas uložený, já právě souditi budu.
3 Nígbà tí ayé àti àwọn ènìyàn ibẹ̀ wárìrì, Èmi ni mo di òpó rẹ̀ mú ṣinṣin.
Rozplynula se země i všickni obyvatelé její, já utvrdím sloupy její. (Sélah)
4 Èmí wí fún àwọn agbéraga pé, ẹ má ṣe gbéraga mọ́; àti sí ènìyàn búburú; ẹ má ṣe gbé ìwo yín sókè.
Dím bláznům: Neblázněte, a bezbožným: Nevyzdvihujte rohů.
5 Ẹ má ṣe gbe ìwo yín sókè sí ọ̀run; ẹ má ṣe sọ̀rọ̀ pẹ̀lú ọrùn líle.”
Nevyzdvihujte proti Nejvyššímu rohů svých, aniž mluvte tvrdošijně.
6 Nítorí ìgbéga kò ti ìlà-oòrùn wá tàbí ní ìwọ̀-oòrùn, bẹ́ẹ̀ ni kì í ṣe láti gúúsù wá.
Nebo ne od východu, ani západu, ani od pouště přichází zvýšení;
7 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run ni olùdájọ́; Ó ń rẹ ẹnìkan sílẹ̀, ó sì ń gbé ẹlòmíràn ga.
Ale Bůh soudce jednoho ponižuje, a druhého povyšuje.
8 Ní ọwọ́ Olúwa ni ago kan wà, ọtí wáìnì náà sì pọ́n, ó kún fún àdàlú, ó fún ọtí àdàlú tí a pò mọ́ òórùn dídùn tí ó tú jáde, àwọn ènìyàn búburú ayé gbogbo mú u pátápátá.
Kalich zajisté jest v rukou Hospodinových, a to vína kalného plný nalitý, z něhož nalévati bude, tak že i kvasnice jeho vyváží, a vypijí všickni bezbožníci země.
9 Ṣùgbọ́n èmi, ó máa ròyìn rẹ títí láé; èmi ó kọrin ìyìn sí Ọlọ́run Jakọbu.
Já pak zvěstovati budu skutky Páně na věčnost, žalmy zpívati budu Bohu Jákobovu.
10 Èmi ó gé ìwo gbogbo ènìyàn búburú, ṣùgbọ́n ìwo àwọn olódodo ni a ó gbéga.
A všecky rohy bezbožníků srážím, rohové pak spravedlivého vyvýšeni budou.

< Psalms 75 >