< Psalms 72 >
1 Ti Solomoni. Fi ìdájọ́ fún àwọn ọba, Ọlọ́run, ọmọ-aládé ni ìwọ fi òdodo rẹ fún.
Sulayman üqün: — I Huda, padixaⱨⱪa ⱨɵkümliringni tapxurƣaysǝn; Padixaⱨning oƣliƣa Ɵz ⱨǝⱪⱪaniyliⱪingni bǝrgǝysǝn.
2 Yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ pẹ̀lú òdodo, yóò sì máa fi ẹ̀tọ́ ṣe ìdájọ́ àwọn tálákà rẹ̀.
Xundaⱪ bolƣanda u Ɵz hǝlⱪing üqün ⱨǝⱪⱪaniyliⱪ bilǝn, Sanga tǝwǝ ezilgǝn mɵminlǝr üqün adilliⱪ bilǝn ⱨɵküm qiⱪiridu;
3 Àwọn òkè ńlá yóò máa mú àlàáfíà fún àwọn ènìyàn àti òkè kéékèèké nípa òdodo.
Taƣlar hǝlⱪⱪǝ tinq-amanliⱪ elip kelidu, Edirliⱪlarmu ⱨǝⱪⱪaniyliⱪ bilǝn xundaⱪ ⱪilidu.
4 Yóò dáàbò bo àwọn tí a pọ́n lójú láàrín àwọn ènìyàn yóò gba àwọn ọmọ aláìní; yóò sì fa àwọn aninilára ya.
Padixaⱨ hǝlⱪ arisidiki ezilgǝnlǝrgǝ adil ⱨɵkümlǝrni qiⱪiridu; U namratlarning balilirini ⱪutⱪuzidu, Zalimlarni bitqit ⱪilidu.
5 Àwọn òtòṣì àti aláìní yóò máa fi ọ̀wọ̀ ńlá fún ọ nígbà gbogbo, níwọ̀n ìgbà tí oòrùn àti òṣùpá bá ń ràn, yóò ti pẹ́ tó, láti ìrandíran.
Xundaⱪ bolƣanda kün wǝ ay yoⱪ bolup kǝtmisila, Əwladtin-ǝwladⱪa hǝlⱪ Sǝndin ǝyminidu.
6 Yóò dàbí òjò tí ó ń rọ̀ sórí pápá ìrẹ́mọ́lẹ̀, bí ọwọ́ òjò tó ń rin ilẹ̀.
U bolsa goya yengidin orƣan otlaⱪⱪa yaƣⱪan yamƣurdǝk, Yǝr suƣiridiƣan ⱨɵl-yeƣinlardǝk qüxidu.
7 Àwọn olódodo yóò gbilẹ̀ ni ọjọ́ rẹ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àlàáfíà yóò sì wà; títí tí òṣùpá kò fi ní sí mọ́.
Uning künliridǝ ⱨǝⱪⱪaniylar ronaⱪ tapidu; Ay yoⱪ bolƣuqǝ tinq-amanliⱪ texip turidu.
8 Yóò máa jẹ ọba láti òkun dé òkun àti láti odò Eufurate títí dé òpin ayé.
U dengizdin-dengizlarƣiqǝ, [Əfrat] dǝryasidin yǝr yüzining qǝtlirigiqǝ ⱨɵküm süridu.
9 Àwọn tí ó wà ní aginjù yóò tẹríba fún un àwọn ọ̀tá rẹ̀ yóò máa lá erùpẹ̀ ilẹ̀.
Qɵl-bayawanda yaxawatⱪanlar uning aldida bax ⱪoyidu; Uning düxmǝnliri topilarni yalaydu.
10 Àwọn ọba Tarṣiṣi àti ti erékùṣù wọn yóò mú ọrẹ wá fún un; àwọn ọba Ṣeba àti Seba wọn ó mú ẹ̀bùn wá fún un.
Tarxixning wǝ arallarning padixaⱨliri uningƣa ⱨǝdiyǝlǝr tǝⱪdim ⱪilidu, Xeba wǝ Sebaning padixaⱨlirimu sowƣatlar sunidu.
11 Gbogbo ọba yóò tẹríba fún un àti gbogbo orílẹ̀-èdè yóò sìn ín.
Dǝrwǝⱪǝ, barliⱪ padixaⱨlar uning aldida sǝjdǝ ⱪilidu; Pütkül ǝllǝr uning hizmitidǝ bolidu;
12 Nítorí yóò gba àwọn aláìní nígbà tí ó bá ń ké, tálákà àti ẹni tí kò ní olùrànlọ́wọ́.
Qünki u pǝryad kɵtürgǝn yoⱪsullarni, Panaⱨsiz ezilgǝnlǝrni ⱪutulduridu;
13 Yóò káàánú àwọn aláìlera àti aláìní yóò pa aláìní mọ́ kúrò nínú ikú.
U yoⱪsul-ajizlarƣa iqini aƣritidu, Yoⱪsullarning jenini ⱪutⱪuzidu;
14 Yóò ra ọkàn wọn padà lọ́wọ́ ẹ̀tàn àti ipá nítorí ẹ̀jẹ̀ wọn ṣọ̀wọ́n níwájú rẹ̀.
Ularning jenini zulum-zomigǝrliktin ⱨɵrlükkǝ qiⱪiridu, Ularning ⱪeni uning nǝziridǝ ⱪimmǝtliktur.
15 Yóò sì pẹ́ ní ayé! A ó sì fún un ní wúrà Ṣeba. Àwọn ènìyàn yóò sì máa gbàdúrà fún un nígbà gbogbo kí a sì bùkún fún un lójoojúmọ́.
[Padixaⱨ] yaxisun! Xebaning altunliridin uningƣa sunulidu; Uning üqün dua tohtawsiz ⱪilinidu; Uningƣa kün boyi bǝht tilinidu;
16 Kí ìkúnwọ́ ọkà wà lórí ilẹ̀; ní orí òkè ni kí ó máa dàgbà kí èso rẹ̀ kí o gbilẹ̀ bí ti Lebanoni yóò máa gbá yìn bí i koríko ilẹ̀.
Yǝr yüzidiki ⱨosul mol bolidu, Ⱨǝtta taƣ qoⱪⱪiliridimu xundaⱪ bolidu. [Miƣ-miƣ] qüxkǝn mewilǝr Liwandiki ormanlardǝk tǝwrinidu; Xǝⱨǝrdikilǝr bolsa daladiki ot-yexilliⱪtǝk güllinidu;
17 Kí orúkọ rẹ̀ kí ó wà títí láé; orúkọ rẹ̀ yóò máa gbilẹ̀ níwọ̀n bí oòrùn yóò ti pẹ́ tó. Wọn ó sì máa bùkún fún ara wọn nípasẹ̀ rẹ. Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ní yóò máa pè mí ní alábùkún fún.
Uning nami mǝnggügǝ ɵqmǝydu, Uning nami ⱪuyax yoⱪalƣuqǝ turidu; Adǝmlǝr uning bilǝn ɵzlirigǝ bǝht tilǝydu, Barliⱪ ǝllǝr uni bǝhtlik dǝp atixidu.
18 Olùbùkún ni Olúwa Ọlọ́run, Ọlọ́run Israẹli, ẹnìkan ṣoṣo tí ó ń ṣe ohun ìyanu.
Israilning Hudasi, Pǝrwǝrdigar Hudaƣa tǝxǝkkür-mǝdⱨiyǝ bolƣay! Karamǝt ixlarni Yaratⱪuqi yalƣuz Udur!
19 Olùbùkún ni orúkọ rẹ̀ tí ó lógo títí láé; kí gbogbo ayé kún fún ògo rẹ̀.
Uning xǝrǝplik namiƣa mǝnggügǝ tǝxǝkkür-mǝdⱨiyǝ oⱪulsun! Uning xan-xɵⱨriti pütkül dunyani ⱪapliƣay! Amin! Wǝ amin!
20 Èyí ni ìparí àdúrà Dafidi ọmọ Jese.
Yǝssǝning oƣli Dawutning dualiri xuning bilǝn tamam boldi.