< Psalms 72 >

1 Ti Solomoni. Fi ìdájọ́ fún àwọn ọba, Ọlọ́run, ọmọ-aládé ni ìwọ fi òdodo rẹ fún.
Toloro amy mpanjakay ty fizakà’o, ry Andrianañahare, vaho amy ana’ i mpanjakaiy ty havantaña’o,
2 Yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ pẹ̀lú òdodo, yóò sì máa fi ẹ̀tọ́ ṣe ìdájọ́ àwọn tálákà rẹ̀.
Hizaka’e an-kahiti’e ondati’oo, o mpisotri’oo an-katò.
3 Àwọn òkè ńlá yóò máa mú àlàáfíà fún àwọn ènìyàn àti òkè kéékèèké nípa òdodo.
Hinday fanintsiñañe am’ ondatio o vohitseo, naho havañonañe o haboañeo.
4 Yóò dáàbò bo àwọn tí a pọ́n lójú láàrín àwọn ènìyàn yóò gba àwọn ọmọ aláìní; yóò sì fa àwọn aninilára ya.
Ho mei’e to o rarake am’ondatioo, ho rombahe’e ty ana’ o poi’eo, vaho ho demohe’e ty mpamorekeke.
5 Àwọn òtòṣì àti aláìní yóò máa fi ọ̀wọ̀ ńlá fún ọ nígbà gbogbo, níwọ̀n ìgbà tí oòrùn àti òṣùpá bá ń ràn, yóò ti pẹ́ tó, láti ìrandíran.
Hañeveñe ama’o iereo naho mbe ey i androy, vaho mbe eñe i volañey, amy ze hene tariratse.
6 Yóò dàbí òjò tí ó ń rọ̀ sórí pápá ìrẹ́mọ́lẹ̀, bí ọwọ́ òjò tó ń rin ilẹ̀.
Ie hizotso manahake ty orañe an-teteke vaho tinatake eo, hoe ereke mampiboboke ty tane.
7 Àwọn olódodo yóò gbilẹ̀ ni ọjọ́ rẹ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àlàáfíà yóò sì wà; títí tí òṣùpá kò fi ní sí mọ́.
Hiraorao amo andro’eo o vañoñeo: vaho am-pierañerañañe vokatse ampara’ te mimosaoñe i volañey.
8 Yóò máa jẹ ọba láti òkun dé òkun àti láti odò Eufurate títí dé òpin ayé.
Ho fehè’e ty boak’ an-driake eñe, pak’an-driak’ añe ka; le boak’ amy sakay pak’amo olon-taneo.
9 Àwọn tí ó wà ní aginjù yóò tẹríba fún un àwọn ọ̀tá rẹ̀ yóò máa lá erùpẹ̀ ilẹ̀.
hilokoloko ama’e o mpimoneñe am-babangoañeo; vaho hitsela lemboke o rafelahi’eo.
10 Àwọn ọba Tarṣiṣi àti ti erékùṣù wọn yóò mú ọrẹ wá fún un; àwọn ọba Ṣeba àti Seba wọn ó mú ẹ̀bùn wá fún un.
Handroroñe ama’e o mpanjaka’ i Tarsiseo naho o tokonoseo; hañenga ama’e o mpanjaka’ i Tsebà naho i Sebào.
11 Gbogbo ọba yóò tẹríba fún un àti gbogbo orílẹ̀-èdè yóò sìn ín.
Eka, hibokokoa’ ze kila mpanjaka, hene fifeheañe ro hitoroñe aze.
12 Nítorí yóò gba àwọn aláìní nígbà tí ó bá ń ké, tálákà àti ẹni tí kò ní olùrànlọ́wọ́.
Himbae’e ty rarake te mitoreo, naho i mpisotriy, vaho i tsy amam-pañimbay.
13 Yóò káàánú àwọn aláìlera àti aláìní yóò pa aláìní mọ́ kúrò nínú ikú.
Hiferenaiña’e ty maifoifo naho o poi’eo, vaho ho rombahe’e ty fiai’ o mavomavoo.
14 Yóò ra ọkàn wọn padà lọ́wọ́ ẹ̀tàn àti ipá nítorí ẹ̀jẹ̀ wọn ṣọ̀wọ́n níwájú rẹ̀.
Ho jebañe’e ami’ty famorekekeañe naho amo hasiahañeo ty fiai’iareo, fa sarotse am-pivazohoa’e eo ty lio’ iareo.
15 Yóò sì pẹ́ ní ayé! A ó sì fún un ní wúrà Ṣeba. Àwọn ènìyàn yóò sì máa gbàdúrà fún un nígbà gbogbo kí a sì bùkún fún un lójoojúmọ́.
Ho velon-dre! hatolotse aze ty volamena’ i Sebà; añonjono halaly ama’e nainai’e, andriaño lomoñandro.
16 Kí ìkúnwọ́ ọkà wà lórí ilẹ̀; ní orí òkè ni kí ó máa dàgbà kí èso rẹ̀ kí o gbilẹ̀ bí ti Lebanoni yóò máa gbá yìn bí i koríko ilẹ̀.
ho vokats’ ampemba i taney, an-dengon-kaboañe ey, le hihelakelake hoe e Lebanone añe o havokara’eo; vaho handrevake hoe ty ahe’ i taney o boak’an-drovao.
17 Kí orúkọ rẹ̀ kí ó wà títí láé; orúkọ rẹ̀ yóò máa gbilẹ̀ níwọ̀n bí oòrùn yóò ti pẹ́ tó. Wọn ó sì máa bùkún fún ara wọn nípasẹ̀ rẹ. Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ní yóò máa pè mí ní alábùkún fún.
Tsy ho tampetse nainai’e ty tahina’e; tsy ho modo aolo’ i àndroy ty tahina’e; vaho hifampitata ty ama’e ondatio, ze kilakila ondaty hanao aze soa-tata.
18 Olùbùkún ni Olúwa Ọlọ́run, Ọlọ́run Israẹli, ẹnìkan ṣoṣo tí ó ń ṣe ohun ìyanu.
Andriaño t’Iehovà Andrianamboatse, Andrianañahare’ Israele, Ie avao ro manao raha tsitantane.
19 Olùbùkún ni orúkọ rẹ̀ tí ó lógo títí láé; kí gbogbo ayé kún fún ògo rẹ̀.
Bangoeñe nainai’e i tahina’e lifo-bolonahetsey; mañàtseke ty tane toy ty enge’e. Ie izay! naho Amena!
20 Èyí ni ìparí àdúrà Dafidi ọmọ Jese.
Migadoñe eo ty ­filolofa’ i Davide, ana’ Iesae.

< Psalms 72 >