< Psalms 72 >

1 Ti Solomoni. Fi ìdájọ́ fún àwọn ọba, Ọlọ́run, ọmọ-aládé ni ìwọ fi òdodo rẹ fún.
Thaburi ya Solomoni Wee Ngai, he mũthamaki ũhoti wa gũtuuanagĩra ciira na kĩhooto, na mũrũ wa mũthamaki ũkĩmũhe ũthingu waku.
2 Yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn rẹ̀ pẹ̀lú òdodo, yóò sì máa fi ẹ̀tọ́ ṣe ìdájọ́ àwọn tálákà rẹ̀.
Nake nĩarĩciiragĩra andũ aku na ũthingu, andũ aku arĩa anyamaarĩku amatuagĩre ciira na kĩhooto.
3 Àwọn òkè ńlá yóò máa mú àlàáfíà fún àwọn ènìyàn àti òkè kéékèèké nípa òdodo.
Irĩma igaatũmaga andũ magaacĩre, natuo tũrĩma tũciarage matunda ma ũthingu.
4 Yóò dáàbò bo àwọn tí a pọ́n lójú láàrín àwọn ènìyàn yóò gba àwọn ọmọ aláìní; yóò sì fa àwọn aninilára ya.
Nĩarĩgitagĩra andũ arĩa anyamaarĩku gatagatĩ ka andũ, na ahonokie ciana cia arĩa abatari; nĩakahehenja arĩa mamahinyagĩrĩria.
5 Àwọn òtòṣì àti aláìní yóò máa fi ọ̀wọ̀ ńlá fún ọ nígbà gbogbo, níwọ̀n ìgbà tí oòrùn àti òṣùpá bá ń ràn, yóò ti pẹ́ tó, láti ìrandíran.
Mũthamaki arotũũra hĩndĩ ĩrĩa yothe riũa rĩgũtũũra, na rĩrĩa rĩothe mweri ũgũtũũra nginya njiarwa na njiarwa.
6 Yóò dàbí òjò tí ó ń rọ̀ sórí pápá ìrẹ́mọ́lẹ̀, bí ọwọ́ òjò tó ń rin ilẹ̀.
Arĩhaanaga ta mbura ĩkiurĩra mũgũnda mũtũgũte, ahaane ta rũthuthuũ ũrĩa rũihũgagia thĩ.
7 Àwọn olódodo yóò gbilẹ̀ ni ọjọ́ rẹ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀ àlàáfíà yóò sì wà; títí tí òṣùpá kò fi ní sí mọ́.
Matukũ-inĩ make andũ arĩa athingu nĩmagatheerema; naguo ũgaacĩru ũingĩhe o nginya rĩrĩa mweri ũgaakorwo ũtarĩ ho.
8 Yóò máa jẹ ọba láti òkun dé òkun àti láti odò Eufurate títí dé òpin ayé.
Agaathanaga kuuma iria rĩmwe nginya rĩrĩa rĩngĩ, na kuuma Rũũĩ rwa Farati o nginya ituri cia thĩ.
9 Àwọn tí ó wà ní aginjù yóò tẹríba fún un àwọn ọ̀tá rẹ̀ yóò máa lá erùpẹ̀ ilẹ̀.
Ndũrĩrĩ cia werũ-inĩ nĩikainamĩrĩra mbere yake, nacio thũ ciake icũne rũkũngũ.
10 Àwọn ọba Tarṣiṣi àti ti erékùṣù wọn yóò mú ọrẹ wá fún un; àwọn ọba Ṣeba àti Seba wọn ó mú ẹ̀bùn wá fún un.
Athamaki a Tarishishi na a mabũrũri marĩa marĩ hũgũrũrũ-inĩ cia kũraya nĩmakamũrehagĩra igooti; nao athamaki a Sheba na Seba nĩmakamũrehagĩra iheo.
11 Gbogbo ọba yóò tẹríba fún un àti gbogbo orílẹ̀-èdè yóò sìn ín.
Athamaki othe makaamũinamĩrĩra, nacio ndũrĩrĩ ciothe imũtungatagĩre.
12 Nítorí yóò gba àwọn aláìní nígbà tí ó bá ń ké, tálákà àti ẹni tí kò ní olùrànlọ́wọ́.
Nĩgũkorwo nĩakahonokia abatari maamũkaĩra, o na arĩa anyamaarie matarĩ na wa kũmateithia.
13 Yóò káàánú àwọn aláìlera àti aláìní yóò pa aláìní mọ́ kúrò nínú ikú.
Nĩakaiguagĩra tha arĩa matarĩ hinya na arĩa abatari, na ahonokie arĩa athĩĩni kuuma kũrĩ gĩkuũ.
14 Yóò ra ọkàn wọn padà lọ́wọ́ ẹ̀tàn àti ipá nítorí ẹ̀jẹ̀ wọn ṣọ̀wọ́n níwájú rẹ̀.
Nĩakamateithũra kuuma kũrĩ arĩa mamahinyagĩrĩria na kuuma haaro-inĩ, nĩgũkorwo thakame yao ĩrĩ bata mũno maitho-inĩ make.
15 Yóò sì pẹ́ ní ayé! A ó sì fún un ní wúrà Ṣeba. Àwọn ènìyàn yóò sì máa gbàdúrà fún un nígbà gbogbo kí a sì bùkún fún un lójoojúmọ́.
Arogĩtũũra hĩndĩ ndaaya! Aroheagwo thahabu ya kuuma Sheba. Arotũũra ahooyagĩrwo nĩ andũ hĩndĩ ciothe, na mamũrathimage mũthenya wothe.
16 Kí ìkúnwọ́ ọkà wà lórí ilẹ̀; ní orí òkè ni kí ó máa dàgbà kí èso rẹ̀ kí o gbilẹ̀ bí ti Lebanoni yóò máa gbá yìn bí i koríko ilẹ̀.
Bũrũri ũrogĩa na bũthi wa ngano kũndũ guothe; ĩrorirũkĩra tũrĩma-igũrũ. Maciaro makuo marothegea ta ma Lebanoni; nakuo matũũra-inĩ andũ marotheerema ta nyeki ya gĩthaka.
17 Kí orúkọ rẹ̀ kí ó wà títí láé; orúkọ rẹ̀ yóò máa gbilẹ̀ níwọ̀n bí oòrùn yóò ti pẹ́ tó. Wọn ó sì máa bùkún fún ara wọn nípasẹ̀ rẹ. Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè ní yóò máa pè mí ní alábùkún fún.
Rĩĩtwa rĩake rĩrotũũra nginya tene; rĩrotũũra o ta ũrĩa riũa rĩgũtũũra. Ndũrĩrĩ ciothe nĩikarathimwo nĩ ũndũ wake, nacio imwĩtage mũndũ mũrathime.
18 Olùbùkún ni Olúwa Ọlọ́run, Ọlọ́run Israẹli, ẹnìkan ṣoṣo tí ó ń ṣe ohun ìyanu.
Goocai Jehova Ngai, o we Ngai wa Isiraeli, o we wiki wĩkaga maũndũ ma magegania.
19 Olùbùkún ni orúkọ rẹ̀ tí ó lógo títí láé; kí gbogbo ayé kún fún ògo rẹ̀.
Rĩĩtwa rĩake rĩu rĩrĩ riiri rĩrogoocagwo nginya tene; nayo thĩ yothe ĩroiyũrwo nĩ riiri wake.
20 Èyí ni ìparí àdúrà Dafidi ọmọ Jese.
Ũcio nĩguo mũthia wa mahooya ma Daudi, mũrũ wa Jesii.

< Psalms 72 >