< Psalms 70 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Ẹ̀bẹ̀. Yára, Ọlọ́run, láti gbà mí là, Olúwa, wá kánkán láti ràn mí lọ́wọ́.
Oh ʼElohim, apresúrate a librarme. Apresúrate, oh Yavé, a socorrerme.
2 Kí àwọn tí ń wá ọkàn mi kí a dójútì wọ́n, kí wọn sì dààmú; kí àwọn tó ń wá ìparun mi yí ẹ̀yìn padà nínú ìtìjú.
Sean avergonzados y humillados Los que buscan mi vida, Sean vueltos atrás y confundidos Los que desean mi mal.
3 Kí a pa wọ́n ní ẹ̀yìn dà fún èrè ìtìjú àwọn tí ń wí pé, “Háà! Háà!”
Sean vueltos atrás a causa de su vergüenza Los que dicen: ¡Ea, ea!
4 Ṣùgbọ́n kí àwọn tí ó ń wá ọ ó máa yọ̀ kí inú wọn kí ó sì máa dùn nípa rẹ, kí àwọn tí ó ń fẹ́ ìgbàlà rẹ máa wí pé, “Jẹ́ kí a gbé Ọlọ́run ga!”
Regocíjense y alégrense en Ti todos los que te buscan. Y aquellos que aman tu salvación digan siempre: ¡Engrandecido sea ʼElohim!
5 Ṣùgbọ́n mo jẹ́ òtòṣì àti aláìní; wa kánkán sí ọ̀dọ̀ mi, Ọlọ́run. Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àti olùdáǹdè mi; Olúwa, má ṣe dúró pẹ́.
Pero yo estoy afligido y menesteroso. Oh ʼElohim, apresúrate a mí. Tú eres mi Ayudador y mi Libertador. Oh Yavé, no demores.

< Psalms 70 >