< Psalms 70 >
1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Ẹ̀bẹ̀. Yára, Ọlọ́run, láti gbà mí là, Olúwa, wá kánkán láti ràn mí lọ́wọ́.
Katoeng kruek zaehoikung hanah. David mah tahmen hnikhaih. Aw Sithaw, karangah na pahlong ah; Aw Angraeng, kai abomh hanah karangah angzo ah.
2 Kí àwọn tí ń wá ọkàn mi kí a dójútì wọ́n, kí wọn sì dààmú; kí àwọn tó ń wá ìparun mi yí ẹ̀yìn padà nínú ìtìjú.
Ka hinghaih lak han pakrong kaminawk loe azathaih tongh o nasoe loe, anghmanghaih hoiah om o nasoe; kai raihaih paek koeh kaminawk loe hnuk amlaem o nasoe loe, palungboenghaih hoiah om o nasoe.
3 Kí a pa wọ́n ní ẹ̀yìn dà fún èrè ìtìjú àwọn tí ń wí pé, “Háà! Háà!”
Kai hanah Aha, Aha, tiah pahnuithuih kaminawk loe azathaih hoiah amlaem o let nasoe.
4 Ṣùgbọ́n kí àwọn tí ó ń wá ọ ó máa yọ̀ kí inú wọn kí ó sì máa dùn nípa rẹ, kí àwọn tí ó ń fẹ́ ìgbàlà rẹ máa wí pé, “Jẹ́ kí a gbé Ọlọ́run ga!”
Nang pakrong kaminawk boih, nang ah anghoe o nasoe loe, nawm o nasoe; na pahlonghaih koeh kaminawk mah, Sithaw loe dungzan khoek to lensawkhaih om nasoe, tiah thui o nasoe.
5 Ṣùgbọ́n mo jẹ́ òtòṣì àti aláìní; wa kánkán sí ọ̀dọ̀ mi, Ọlọ́run. Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àti olùdáǹdè mi; Olúwa, má ṣe dúró pẹ́.
Toe kai loe amtang moe, caaknaek vawt kami ah ka oh; Aw Sithaw, kai khaeah karangah angzo ah; nang loe kai bomkung hoi kai pahlongkung ah na oh; aw Angraeng, akra hmah.