< Psalms 70 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Ẹ̀bẹ̀. Yára, Ọlọ́run, láti gbà mí là, Olúwa, wá kánkán láti ràn mí lọ́wọ́.
Gode! Na gaga: ma! Hina Gode! Wahadafa, na fidima!
2 Kí àwọn tí ń wá ọkàn mi kí a dójútì wọ́n, kí wọn sì dààmú; kí àwọn tó ń wá ìparun mi yí ẹ̀yìn padà nínú ìtìjú.
Amo dunu na fane legemusa: manebe da hasalasili amola ededenanesima: ma! Amola dunu amo da na bidi hamosu ba: beba: le, hahawane gala, ili ogobele gogosiasu ba: ma: ma!
3 Kí a pa wọ́n ní ẹ̀yìn dà fún èrè ìtìjú àwọn tí ń wí pé, “Háà! Háà!”
Dunu amo da nama lasogole oufesega: sa, amo hasalima! Amasea, ilia da bagade beda: mu.
4 Ṣùgbọ́n kí àwọn tí ó ń wá ọ ó máa yọ̀ kí inú wọn kí ó sì máa dùn nípa rẹ, kí àwọn tí ó ń fẹ́ ìgbàlà rẹ máa wí pé, “Jẹ́ kí a gbé Ọlọ́run ga!”
Dunu huluane da Dima masea, ilia da nodone hahawane ba: mu da defea. Dunu huluane amo da Dia gaga: su lai dagoiba: le, Dima nodosa, ilia da eso huluane, “Gode da baligili bagadedafa,” sia: mu da defea.
5 Ṣùgbọ́n mo jẹ́ òtòṣì àti aláìní; wa kánkán sí ọ̀dọ̀ mi, Ọlọ́run. Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àti olùdáǹdè mi; Olúwa, má ṣe dúró pẹ́.
Na da gasa hamedeidafa! Gode! Nama hedolo misa! Hina Gode! Di da na gaga: su gala! Nama hedolo fidila misa!

< Psalms 70 >