< Psalms 69 >

1 Fún adarí orin. Tí ohùn “Àwọn Lílì.” Ti Dafidi. Gbà mí, Ọlọ́run, nítorí omi ti kún dé ọrùn mi.
E HOOLA mai ia'u, e ke Akua; No ka mea, ua komo mai na wai i ko'u uhane.
2 Mo ń rì nínú irà jíjìn, níbi tí kò sí ibi ìfẹsẹ̀lé. Mo ti wá sínú omi jíjìn; ìkún omi bò mí mọ́lẹ̀.
Ke palemo nei au i ka lepo poho hohonu, kahi e ku ole ai: Ua hiki mai nei au i na wai hohonu; Ke kahe nei no hoi na muliwai maluna o'u.
3 Agara dá mi, mo ń pè fún ìrànlọ́wọ́; ọ̀fun mí gbẹ, ojú mi ṣú, nígbà tí èmi dúró de Ọlọ́run mi.
Ua luhi au i kuu kahea ana aku, ua maloo kuu puu: Pau e kuu mau maka i ko'u kali ana no kuu Akua.
4 Àwọn tí ó kórìíra mi láìnídìí wọ́n ju irun orí mi lọ, púpọ̀ ni àwọn ọ̀tá mi láìnídìí, àwọn tí ń wá láti pa mí run. A fi ipá mú mi láti san ohun tí èmi kò jí.
Ua lehulehu aku i na lauoho o kuu poo ka poe huhu hala ole mai ia'u; Ua ikaika hoi ka poe manao e pepehi mai ia'u, e ku e hewa mai ana ia'u: Alaila hoihoi aku au i ka mea a'u i kaili ole ai.
5 Ìwọ mọ òmùgọ̀ mi, Ọlọ́run; ẹ̀bi mi kò pamọ́ lójú rẹ.
E ke Akua, ua ike mai oe i ko'u naaupo: Aole hoi i nalo ko'u mau hewa ia oe.
6 Má ṣe dójútì àwọn tí ó ní ìrètí nínú rẹ nítorí mi, Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun; má ṣe jẹ́ kí àwọn tó ń wá ọ dààmú nítorí mi, Ọlọ́run Israẹli.
Mai noho a hoohilahilaia no'u nei ka poe hilinai ia oe, e ka Haku, Iehova Sabaota. Mai noho a hoohokaia no'u nei ka poe imi ia oe, e ke Akua o ka Iseraela.
7 Nítorí rẹ ni mo ń ru ẹ̀gàn, ìtìjú sì bo ojú mi.
No ka mea, nou la i halihali ai au i ka hoinoia; Ua uhi mai ka hilahila i ko'u maka.
8 Mo jẹ́ àjèjì si àwọn arákùnrin mi; àlejò sí àwọn arákùnrin ìyá mi;
Ua lilo au i malihini i ko'u mau hoahanau, He kanaka e hoi i na keiki a ko'u makuwahine.
9 nítorí ìtara ilé rẹ jẹ mí run, àti ẹ̀gàn àwọn tí ń gàn ọ́ ṣubú lù mí.
No ka mea, ua hoopauia au e ka manao ikaika no kou hale: A o na hoino ana o ka poe hoino ia oe, ua haule mai ia maluna iho o'u.
10 Nígbà tí mo sọkún tí mo sì ń fi àwẹ̀ jẹ ara mi ní ìyà èyí náà sì dín ẹ̀gàn mi kù;
A uwe au, a hahau hoi i kuu uhane me ka hookeai ana, Oia ka'u mea i hoinoia mai ai.
11 nígbà tí mo wọ aṣọ àkísà, àwọn ènìyàn ń pa òwe mọ́ mi.
A aahu iho la au i ke kapa ino; Lilo au i mea hoohiki wale ia.
12 Àwọn tí ó jókòó ní ẹnu ibodè ń bú mi, mo sì di orin àwọn ọ̀mùtí.
Ua olelo ku e mai ia'u ka poe noho ma ka ipuka; A lilo hoi au i mele na ka poe inu i ka mea ona.
13 Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti èmi ni ìwọ ni èmi ń gbàdúrà mi sí Olúwa, ní ìgbà ìtẹ́wọ́gbà Ọlọ́run, nínú ìfẹ́ títóbi rẹ, dá mi lóhùn pẹ̀lú ìgbàlà rẹ tí ó dájú.
Aka, owau nei la, aia ia oe ka'u pule, o Iehova, I ka wa maliuia; E ke Akua, ma ka nui o kou aloha, e hoolohe mai ia'u, I ka oiaio o kou ola.
14 Gbà mí kúrò nínú ẹrẹ̀, má ṣe jẹ́ kí n rì; gbà mí lọ́wọ́ àwọn tí ó kórìíra mi, kúrò nínú ibú omi.
E hoopakele ia'u i ka lepo poho, aole hoi au e palemo: E hoopakeleia au i ka poe inaina mai ia'u, a i na wai hohonu.
15 Má ṣe jẹ́ kí ìkún omi bò mí mọ́lẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni má ṣe jẹ́ kí ọ̀gbìn gbé mi mì kí o má sì ṣe jẹ́ kí ihò pa ẹnu rẹ̀ dé mọ́ mi.
Mai noho a kahe ka waikahe maluna o'u; Mai noho a ale mai ka hohonu ia'u; Aole hoi e pani ka lua i kona waha maluna o'u.
16 Dá mí lóhùn, Olúwa, nínú ìṣeun ìfẹ́ rẹ; nínú ọ̀pọ̀ àánú rẹ yípadà sí mi.
E hoolohe mai ia'u, e Iehova, no ka mea, he pono kou lokomaikai; Mamuli o ka nui loa o kou aloha, e maliu mai ia'u.
17 Má ṣe pa ojú rẹ mọ́ fún ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ: yára dá mi lóhùn, nítorí mo wà nínú ìpọ́njú.
Mai hoonalo i kou maka i kau kauwa; No ka mea, ua pilikia au: E hoolohe koke mai oe ia'u.
18 Súnmọ́ tòsí kí o sì gbà mí là; rà mí padà nítorí àwọn ọ̀tá mi.
E hookokoke mai i kuu uhane, a e hoola mai ia ia: E hoopakele ia'u no ko'u poe enemi.
19 Ìwọ ti mọ ẹ̀gàn mi, ìtìjú mi àti àìlọ́lá; gbogbo àwọn ọ̀tá mi wà níwájú rẹ.
Ua ike ae nei oe i ko'u hoinoia, ko'u hoohilahilaia, a me ko'u heneheneia: Imua no hoi ou ko'u mau enemi a pau.
20 Ẹ̀gàn ba ọkàn mi jẹ́, wọ́n fi mí sílẹ̀ láìsí ìrànlọ́wọ́; mo ń wá aláàánú, ṣùgbọ́n kò sí, mo ń wá olùtùnú, ṣùgbọ́n n kò rí ẹnìkankan.
Ua haehae ko'u naau i ka hoinoia mai, a kaumaha loa au; Kali aku la au i mea e menemene mai, aole hoi; A i mau mea hooluolu mai, aole i loaa ia'u.
21 Wọ́n fi òróró fún mi pẹ̀lú ohun jíjẹ mi, àti ní òùngbẹ mi, wọ́n fi ọtí kíkan fún mi.
Ua haawi mai la lakou i ka mea awahia i ai na'u; A i kuu makewai ana ua hoohainu mai lakou ia'u i ka vinega.
22 Jẹ́ kí tábìlì wọn kí ó di ìkẹ́kùn ní iwájú wọn, kí ó sì di okùn dídẹ fún àwọn tó wà ní àlàáfíà.
E lilo no ko lakou papaaina i pahele imua o lakou: A o ko lakou uku i mea e hihia ai.
23 Kí ojú wọn kì í ó ṣókùnkùn, kí wọn má ṣe ríran, kí ẹ̀yin wọn di títẹ̀ títí láé.
E hoopouliia ko lakou mau maka i ike ole lakou; A e hoohaalulu mau no hoi oe i ko lakou mau puhaka.
24 Tú ìbínú rẹ jáde sí wọn; kí ìbínú gbígbóná rẹ bò wọ́n mọ́lẹ̀.
E ninini iho no oe i kou inaina maluna o lakou; A e loohia lakou i kou huhu wela.
25 Kí ibùjókòó wọn di ahoro; kí ẹnikẹ́ni má ṣe gbé nínú wọn.
E neoneo no hoi ko lakou hale; Aohe mea e noho iloko o ko lakou mau halelewa.
26 Nítorí wọ́n ń ṣe inúnibíni sí ẹni tí ìwọ ti lù, àti ìrora àwọn tí ó ti ṣèṣe.
No ka mea, ua alualu hewa lakou i ka mea au i hahau ai; A kamailio lakou he mea kaumaha no na mea au e hoeha mai.
27 Fi ẹ̀sùn kún ẹ̀sùn wọn; Má ṣe jẹ́ kí wọn pín nínú ìgbàlà rẹ.
E hookui i ka hewa maluna o ko lakou hewa: Aole hoi lakou e komo iloko o kou hoaponoia.
28 Jẹ́ kí a yọ wọ́n kúrò nínú ìwé ìyè kí á má kà wọ́n pẹ̀lú àwọn olódodo.
E hoonaloia lakou mailoko aku o ka buke a ka poe ola, Aole lakou e kakau pu ia me ka poe pono.
29 Ṣùgbọ́n tálákà àti ẹni-ìkáàánú ni èmí, Ọlọ́run, jẹ́ kí ìgbàlà rẹ gbé mi lékè.
Aka, ua ilihune au a ua kaumaha no hoi; E hookiekie kou ola ia'u, e ke Akua.
30 Èmi yóò fi orin gbé orúkọ Ọlọ́run ga èmi yóò fi ọpẹ́ gbé orúkọ rẹ̀ ga.
E hoolea aku au i ka inoa o ke Akua, ma ka himeni; A e hoonui aku ia ia me ka hoomaikai ana.
31 Eléyìí tẹ́ Olúwa lọ́rùn ju ọ̀dá màlúù lọ ju akọ màlúù pẹ̀lú ìwo rẹ̀ àti bàtà rẹ̀.
Ua oi aku ka pono o keia ia Iehova mamua o ka bipi kane, A o ka bipi opiopio mea pepeiaohao me na maiuu.
32 Àwọn òtòṣì yóò rí, wọn yóò sì yọ̀: ẹ̀yin yóò wá Ọlọ́run, ọkàn yín yóò sì wà láààyè!
E ike hoi ka poe hoohaahaa, a e hauoli hoi: E imi ana i ke Akua, e ola ko oukou naau.
33 Olúwa, gbọ́ ti aláìní, kì ó sì kọ àwọn ìgbèkùn sílẹ̀.
No ka mea, ua hoolohe mai o Iehova i ka poe ilihune; Aole hoi ia i hoowahawaha i kona poe i hoopaaia.
34 Kí ọ̀run àti ayé yìn ín, òkun àti àwọn tí ń gbé inú rẹ̀,
E hoomaikai ka lani a me ka honua ia ia; O na kai, a me na mea a pau e holo ana maloko olaila.
35 nítorí tí Ọlọ́run yóò gba Sioni là yóò sì tún àwọn ìlú Juda wọ̀nyí kọ́. Kí wọn ó lè máa gbé ibẹ̀, kí wọn ó lè máa ní ní ilẹ̀ ìní;
No ka mea, e hoola no ke Akua ia Ziona, A e kukulu hoi i na kulanakauhale o Iuda; I noho lakou ilaila, a e lilo ia no lakou.
36 àwọn ọmọ ọmọ ọ̀dọ̀ ni yóò máa jogún rẹ̀, àwọn tí ó fẹ́ orúkọ rẹ ni yóò máa gbé inú rẹ̀.
E loaa mai no hoi ia i na hua a kana mau kauwa: A malaila e noho ai ka poe makemake i kona inoa.

< Psalms 69 >