< Psalms 68 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu. Orin. Kí Ọlọ́run kí ó dìde, kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ kí ó fọ́nká; kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ kí ó sá níwájú rẹ̀.
Ustaæe Bog, i rasuæe se neprijatelji njegovi, i pobjeæi æe od lica njegova koji mrze na nj.
2 Bí ìjì ti ń fẹ́ èéfín lọ, kí ó fẹ́ wọn lọ; bí ìda ti í yọ́ níwájú iná, kí olùṣe búburú ṣègbé níwájú Ọlọ́run.
Ti æeš ih razagnati kao dim što se razgoni; kao što se vosak topi od ognja, tako æe bezbožnici izginuti od lica Božijega.
3 Ṣùgbọ́n kí inú olódodo kí ó dùn kí ó sì kún fún ayọ̀ níwájú Ọlọ́run; kí inú wọn kí ó dùn, kí ó sì kún fún ayọ̀.
A pravednici æe se veseliti, radovaæe se pred Bogom, i slaviti u radosti.
4 Ẹ kọrin sí Ọlọ́run, ẹ kọrin ìyìn sí i, ẹ la ọ̀nà fún ẹni tí ń rékọjá ní aginjù. Olúwa ni orúkọ rẹ̀, kí ẹ sì máa yọ̀ níwájú rẹ̀.
Pojte Bogu, popijevajte imenu njegovu; ravnite put onome što ide preko pustinje; Gospod mu je ime, radujte mu se.
5 Baba àwọn aláìní baba àti onídàájọ́ àwọn opó ni Ọlọ́run ní ibùgbé rẹ̀ mímọ́
Otac je sirotama i sudija udovicama Bog u svetome stanu svom.
6 Ọlọ́run gbé aláìlera kalẹ̀ nínú ìdílé, ó darí àwọn ẹlẹ́wọ̀n pẹ̀lú orin, ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́tẹ̀ ní ń gbé nínú ilẹ̀ gbígbẹ.
Bog samcima daje zadrugu, sužnje izvodi na mjesta obilna, a nepokorni žive gdje je suša.
7 Nígbà tí ìwọ bá jáde lónìí níwájú àwọn ènìyàn rẹ, Ọlọ́run, tí ń kọjá lọ láàrín aginjù, (Sela)
Bože! kad si išao pred narodom svojim, kad si išao preko pustinje,
8 Ilẹ̀ mì títí, àwọn ọ̀run ń rọ òjò jáde, níwájú Ọlọ́run, ẹni Sinai, níwájú Ọlọ́run, Ọlọ́run Israẹli.
Zemlja se tresijaše, i nebo se rastapaše od lica Božijega, i ovaj Sinaj od lica Boga, Boga Izrailjeva.
9 Ìwọ fún wa ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ òjò, Ọlọ́run; ìwọ tu ilẹ̀ ìní rẹ̀ lára nígbà tí ó rẹ̀ ẹ́ tan.
Blagodatni si dažd izlivao, Bože, i kad iznemagaše dostojanje tvoje, ti si ga krijepio.
10 Àwọn ènìyàn rẹ tẹ̀dó síbẹ̀ nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìní rẹ, Ọlọ́run, ìwọ pèsè fún àwọn aláìní.
Stado tvoje življaše ondje; po dobroti svojoj, Bože, ti si gotovio hranu jadnome.
11 Olúwa ti pàṣẹ ọ̀rọ̀, púpọ̀ ní ogun àwọn ẹni tí ó ń ròyìn rẹ̀.
Gospod daje rijeè; glasnika veliko je mnoštvo.
12 “Àwọn ọba àti àwọn ológun yára sálọ; obìnrin tí ó sì jókòó ni ilé ní ń pín ìkógun náà.
Carevi nad vojskama bježe, bježe, a koja sjedi doma, dijeli plijen.
13 Nígbà tí ẹ̀yin dùbúlẹ̀ láàrín agbo ẹran, nígbà náà ni ẹ̀yin ó dàbí ìyẹ́ àdàbà ti a bò ní fàdákà, àti ìyẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú wúrà pupa.”
Smirivši se u svojim krajevima, vi ste kao golubica, kojoj su krila posrebrena a perje joj se zlatni.
14 Nígbà tí Olódùmarè fọ́n àwọn ọba ká ní ilẹ̀ náà, ó dàbí òjò dídi ní Salmoni.
Kad je svemoguæi rasipao careve na ovoj zemlji, ona se blistaše kao snijeg na Selmonu.
15 Òkè Baṣani jẹ́ òkè Ọlọ́run; òkè tí ó ní orí púpọ̀ ni òkè Baṣani.
Gora je Vasanska gora Božija; gora je Vasanska gora humovita.
16 Kí ló dé tí ẹ̀yin fi ń ṣe ìlara, ẹ̀yin òkè wúwo, òkè tí Ọlọ́run ti fẹ́ láti jẹ ọba níbi tí Olúwa fúnra rẹ̀ yóò máa gbé títí láé?
Zašto gledate zavidljivo, gore humovite? Evo gora, na kojoj omilje Bogu živjeti, i na kojoj æe Gospod živjeti dovijeka.
17 Ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ni kẹ̀kẹ́ ogun Ọlọ́run ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rún; Olúwa ń bẹ láàrín wọn, ní Sinai ni ibi mímọ́ rẹ̀.
Kola Božijih ima (sila) tisuæe tisuæa. Meðu njima je Gospod, Sinaj u svetinji.
18 Ìwọ ti gòkè sí ibi gíga ìwọ ti di ìgbèkùn ní ìgbèkùn lọ; ìwọ ti gba ẹ̀bùn fún ènìyàn: nítòótọ́, fún àwọn ọlọ̀tẹ̀ pẹ̀lú, kí Olúwa Ọlọ́run lè máa bá wọn gbé.
Ti si izašao na visinu, doveo si roblje, primio darove za ljude, a i za one koji se protive da ovdje nastavaš, Gospode Bože!
19 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Olùgbàlà wa, ẹni tí ó ń fi ojoojúmọ́ gba ẹrù wa rù. (Sela)
Blagosloven Gospod svaki dan! Ako nas ko pretovara, Bog nam pomaže.
20 Ọlọ́run wa jẹ́ Ọlọ́run tó ń gbàlà àti sí Olúwa Olódùmarè ni ó ń gbà wá lọ́wọ́ ikú.
Ovaj je Bog naš Bog spasitelj, u vlasti su Gospodu vrata smrtna.
21 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò tẹ orí àwọn ọ̀tá rẹ̀, àti agbárí onírun àwọn tó ń tẹ̀síwájú nínú ẹ̀ṣẹ̀ wọn
Gospod satire glavu neprijateljima svojim i vlasato tjeme onoga koji ostaje u bezakonju svojem.
22 Olúwa wí pé, “Èmi ó mú wọn wá láti Baṣani; èmi ó mú wọn wá láti ibú omi Òkun,
Reèe Gospod: od Vasana æu dovesti, dovešæu iz dubine morske,
23 kí ẹsẹ̀ rẹ kí ó le pọ́n ní inú ẹ̀jẹ̀ àwọn ọ̀tá rẹ, àti ahọ́n àwọn ajá rẹ ní ìpín tiwọn lára àwọn ọ̀tá rẹ.”
Da ti ogrezne noga u krvi neprijateljskoj i jezik pasa tvojih da je liže.
24 Wọ́n ti rí ìrìn rẹ, Ọlọ́run, ìrìn Ọlọ́run mi àti ọba mi ní ibi mímọ́ rẹ̀.
Vidješe kako ideš, Bože, kako sveto ide Bog moj, car moj.
25 Àwọn akọrin wà ní iwájú, àwọn olórin wà lẹ́yìn; àwọn ọmọbìnrin tí ń lu ṣaworo sì wà pẹ̀lú wọn.
Naprijed iðahu pjevaèi, za njima sviraèi sred djevojaka s bubnjima:
26 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa ní ẹgbẹgbẹ́; àní fún Olúwa ẹ̀yin tí ó ti orísun Israẹli wá.
“Na saboru blagosiljajte Gospoda Boga, koji ste iz izvora Izrailjeva!”
27 Níbẹ̀ ní ẹ̀yà kékeré Benjamini wà, tí ó ń darí wọn, níbẹ̀ ni àwọn ọmọ-aládé Juda, níbẹ̀ ni àwọn ọmọ-aládé Sebuluni àti tí Naftali.
Ondje mladi Venijamin, starješina njihov; knezovi Judini, vladaoci njihovi; knezovi Zavulonovi, knezovi Neftalimovi.
28 Pàṣẹ agbára rẹ, Ọlọ́run; fi agbára rẹ hàn wá, Ọlọ́run, gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti ṣe ní ìṣáájú.
Bog tvoj darovao ti je silu. Utvrdi, Bože, ovo što si uèinio za nas!
29 Nítorí tẹmpili rẹ ni Jerusalẹmu àwọn ọba yóò mú ẹ̀bùn wá fún ọ.
U crkvi tvojoj, u Jerusalimu, carevi æe prinositi dare.
30 Bá àwọn ẹranko búburú wí, tí ń gbé láàrín eèsún ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn akọ màlúù pẹ̀lú àwọn ọmọ màlúù títí olúkúlùkù yóò fi foríbalẹ̀ pẹ̀lú ìwọ̀n fàdákà: tú àwọn ènìyàn tí ń ṣe inú dídùn sí ogun ká.
Ukroti zvijer u ritu, kod volova s teocima naroda, da bi popadali pred tobom sa šipkama srebra; raspi narode koji žele bojeve.
31 Àwọn ọmọ-aládé yóò wá láti Ejibiti; Etiopia yóò na ọwọ́ rẹ̀ sí Ọlọ́run.
Doæi æe vlastela iz Misira, Etiopija æe pružiti ruke svoje k Bogu.
32 Kọrin sí Ọlọ́run, ẹ̀yin ìjọba ayé, kọrin ìyìn sí Olúwa, (Sela)
Carstva zemaljska, pojte Bogu, popijevajte Gospodu,
33 Sí ẹni tí ń gun ọ̀run dé ọ̀run àtijọ́ lókè, tó ń fọhùn rẹ̀, ohùn ńlá.
Koji sjedi na nebesima nebesa iskonskih. Evo grmi glasom jakim.
34 Kéde agbára Ọlọ́run, ọláńlá rẹ̀ wà lórí Israẹli, tí agbára rẹ̀ wà lójú ọ̀run.
Dajte slavu Bogu; velièanstvo je njegovo nad Izrailjem i (sila) njegova na oblacima.
35 Ìwọ ní ẹ̀rù, Ọlọ́run, ní ibi mímọ́ rẹ; Ọlọ́run Israẹli fi agbára àti okun fún àwọn ènìyàn rẹ. Olùbùkún ní Ọlọ́run!
Divan si, Bože, u svetinji svojoj! Bog Izrailjev daje silu i krjepost narodu. Blagosloven Bog!

< Psalms 68 >