< Psalms 68 >

1 Fún adarí orin. Ti Dafidi. Saamu. Orin. Kí Ọlọ́run kí ó dìde, kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ kí ó fọ́nká; kí àwọn ọ̀tá rẹ̀ kí ó sá níwájú rẹ̀.
Ki te tino kaiwhakatangi. He himene, he waiata na Rawiri. Kia ara te Atua, kia marara ona hoariri: kia whati hoki i tona aroaro te hunga e kino ana ki a ia.
2 Bí ìjì ti ń fẹ́ èéfín lọ, kí ó fẹ́ wọn lọ; bí ìda ti í yọ́ níwájú iná, kí olùṣe búburú ṣègbé níwájú Ọlọ́run.
Aia atu ratou, peratia me te paowa e aia ana: kia rite ki te ware pi e rewa ana i te kapura te ngaromanga o te hunga kino i te aroaro o te Atua.
3 Ṣùgbọ́n kí inú olódodo kí ó dùn kí ó sì kún fún ayọ̀ níwájú Ọlọ́run; kí inú wọn kí ó dùn, kí ó sì kún fún ayọ̀.
Kia koa ia te hunga tika; kia hari i te aroaro o te Atua: ae ra, kia tino hari pu ratou.
4 Ẹ kọrin sí Ọlọ́run, ẹ kọrin ìyìn sí i, ẹ la ọ̀nà fún ẹni tí ń rékọjá ní aginjù. Olúwa ni orúkọ rẹ̀, kí ẹ sì máa yọ̀ níwájú rẹ̀.
Waiata ki te Atua, himenetia tona ingoa; opehia ake he huanui mo tana hariata i nga koraha; tona ingoa ko IHA; kia hari hoki ki tona aroaro.
5 Baba àwọn aláìní baba àti onídàájọ́ àwọn opó ni Ọlọ́run ní ibùgbé rẹ̀ mímọ́
Hei matua mo nga pani, hei kaiwhakarite mo nga pouaru, te Atua i tona nohoanga tapu.
6 Ọlọ́run gbé aláìlera kalẹ̀ nínú ìdílé, ó darí àwọn ẹlẹ́wọ̀n pẹ̀lú orin, ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́tẹ̀ ní ń gbé nínú ilẹ̀ gbígbẹ.
E whakanohoia ana e te Atua te mokemoke ki te whare; e whakaputaina ana e ia nga herehere ki te ora: ko te hunga tutu ia e noho i te wahi waikore.
7 Nígbà tí ìwọ bá jáde lónìí níwájú àwọn ènìyàn rẹ, Ọlọ́run, tí ń kọjá lọ láàrín aginjù, (Sela)
E te Atua, i tou haerenga atu i mua i tau iwi: i tou haerenga i te koraha; (Hera)
8 Ilẹ̀ mì títí, àwọn ọ̀run ń rọ òjò jáde, níwájú Ọlọ́run, ẹni Sinai, níwájú Ọlọ́run, Ọlọ́run Israẹli.
I wiri te whenua, i tuturu iho ano nga rangi i te aroaro o te Atua; me taua Hinai ano i te aroaro o te Atua, o te Atua o Iharaira.
9 Ìwọ fún wa ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ òjò, Ọlọ́run; ìwọ tu ilẹ̀ ìní rẹ̀ lára nígbà tí ó rẹ̀ ẹ́ tan.
I taia mai, e koe, e te Atua, he ua nui; a i tou kainga e ruwha ana ka whakaukia e koe.
10 Àwọn ènìyàn rẹ tẹ̀dó síbẹ̀ nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìní rẹ, Ọlọ́run, ìwọ pèsè fún àwọn aláìní.
I noho tau whakaminenga ki reira: na tou pai, e te Atua, i mea kai ai koe ma nga rawakore.
11 Olúwa ti pàṣẹ ọ̀rọ̀, púpọ̀ ní ogun àwọn ẹni tí ó ń ròyìn rẹ̀.
Ka homai e Ihowa te kupu: he ope nui nga wahine whakapuaki.
12 “Àwọn ọba àti àwọn ológun yára sálọ; obìnrin tí ó sì jókòó ni ilé ní ń pín ìkógun náà.
Whati rawa nga kingi o nga taua: a ko te wahine i noho i te whare, kei te tuwha i nga parakete.
13 Nígbà tí ẹ̀yin dùbúlẹ̀ láàrín agbo ẹran, nígbà náà ni ẹ̀yin ó dàbí ìyẹ́ àdàbà ti a bò ní fàdákà, àti ìyẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú wúrà pupa.”
I a koutou ka takoto noa i nga takotoranga hipi, he rite ki nga pakau o te kukupa kua paparuatia nei ki te hiriwa, ona hou ki te koura whero.
14 Nígbà tí Olódùmarè fọ́n àwọn ọba ká ní ilẹ̀ náà, ó dàbí òjò dídi ní Salmoni.
I te whakamararatanga a te Kaha Rawa i nga kingi i reira, koia ano kei te hukarere o Taramono te ma.
15 Òkè Baṣani jẹ́ òkè Ọlọ́run; òkè tí ó ní orí púpọ̀ ni òkè Baṣani.
He maunga Atua a Maunga Pahana; he maunga tiketike a Maunga Pahana.
16 Kí ló dé tí ẹ̀yin fi ń ṣe ìlara, ẹ̀yin òkè wúwo, òkè tí Ọlọ́run ti fẹ́ láti jẹ ọba níbi tí Olúwa fúnra rẹ̀ yóò máa gbé títí láé?
He aha koutou ka titiro titaha ai, e nga maunga tiketike, ki te maunga i hiahiatia nei e te Atua kia nohoia e ia? ae, ka nohoia e Ihowa ake ake.
17 Ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ni kẹ̀kẹ́ ogun Ọlọ́run ẹgbẹ̀rún lọ́nà ẹgbẹ̀rún; Olúwa ń bẹ láàrín wọn, ní Sinai ni ibi mímọ́ rẹ̀.
Ko nga hariata a te Atua, e rua tekau mano, mano mano iho; kei roto i a ratou te Ariki, me te mea ko Hinai, ko te wahi tapu.
18 Ìwọ ti gòkè sí ibi gíga ìwọ ti di ìgbèkùn ní ìgbèkùn lọ; ìwọ ti gba ẹ̀bùn fún ènìyàn: nítòótọ́, fún àwọn ọlọ̀tẹ̀ pẹ̀lú, kí Olúwa Ọlọ́run lè máa bá wọn gbé.
Kua kake koe ki runga, kua whakaraua e koe te whakarau: kua riro i a koe he ohaoha mo te tangata; ae, mo te hunga tutu ano, kia noho ai a Ihowa, te Atua ki a ratou.
19 Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Olùgbàlà wa, ẹni tí ó ń fi ojoojúmọ́ gba ẹrù wa rù. (Sela)
Kia whakapaingia te Ariki, e whakawaha nei i ta tatou pikaunga i tenei ra, i tenei ra, te Atua o to tatou whakaoranga. (Hera)
20 Ọlọ́run wa jẹ́ Ọlọ́run tó ń gbàlà àti sí Olúwa Olódùmarè ni ó ń gbà wá lọ́wọ́ ikú.
Ko to tatou Atua te Atua o te whakaoranga: na Ihowa ano, na te Ariki, nga putanga ake i te mate.
21 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run yóò tẹ orí àwọn ọ̀tá rẹ̀, àti agbárí onírun àwọn tó ń tẹ̀síwájú nínú ẹ̀ṣẹ̀ wọn
Ka maru ia i te Atua te matenga o ona hoariri: me te tumuaki huruhuru o te tangata e haere tonu ana i ana kino.
22 Olúwa wí pé, “Èmi ó mú wọn wá láti Baṣani; èmi ó mú wọn wá láti ibú omi Òkun,
I mea te Ariki, Ka whakahokia mai e ahau i Pahana, ka whakahokia mai e ahau taku iwi i nga rire o te moana:
23 kí ẹsẹ̀ rẹ kí ó le pọ́n ní inú ẹ̀jẹ̀ àwọn ọ̀tá rẹ, àti ahọ́n àwọn ajá rẹ ní ìpín tiwọn lára àwọn ọ̀tá rẹ.”
Kia toua ai tou waewae ki te toto, kia whiwhi ai te arero o au kuri ki tana wahi o ou hoariri.
24 Wọ́n ti rí ìrìn rẹ, Ọlọ́run, ìrìn Ọlọ́run mi àti ọba mi ní ibi mímọ́ rẹ̀.
I kite ratou, e te Atua, i ou haerenga, i nga haerenga o toku Atua, o toku Kingi, i te wahi tapu.
25 Àwọn akọrin wà ní iwájú, àwọn olórin wà lẹ́yìn; àwọn ọmọbìnrin tí ń lu ṣaworo sì wà pẹ̀lú wọn.
Ko nga kaiwaiata i haere i mua, i muri ko nga kaiwhakatangi, i waenganui o nga kotiro e patupatu ana i nga timipera.
26 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa ní ẹgbẹgbẹ́; àní fún Olúwa ẹ̀yin tí ó ti orísun Israẹli wá.
Whakapaingia te Atua i roto i nga whakaminenga, te Ariki hoki, e nga mea i puta mai i te matapuna o Iharaira.
27 Níbẹ̀ ní ẹ̀yà kékeré Benjamini wà, tí ó ń darí wọn, níbẹ̀ ni àwọn ọmọ-aládé Juda, níbẹ̀ ni àwọn ọmọ-aládé Sebuluni àti tí Naftali.
Kei reira a Pineamine, te whakaotinga, to ratou ariki, nga rangatira o Hura, me to ratou ropu, nga rangatira o Hepurona, me nga rangatira o Napatari.
28 Pàṣẹ agbára rẹ, Ọlọ́run; fi agbára rẹ hàn wá, Ọlọ́run, gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti ṣe ní ìṣáájú.
Kua oti he kaha mou te whakahau iho e tou Atua: whakaukia, e te Atua, tau i mea ai mo matou.
29 Nítorí tẹmpili rẹ ni Jerusalẹmu àwọn ọba yóò mú ẹ̀bùn wá fún ọ.
Ka maua mai e nga kingi he hakari ki a koe, mo tou temepara i Hiruharama.
30 Bá àwọn ẹranko búburú wí, tí ń gbé láàrín eèsún ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn akọ màlúù pẹ̀lú àwọn ọmọ màlúù títí olúkúlùkù yóò fi foríbalẹ̀ pẹ̀lú ìwọ̀n fàdákà: tú àwọn ènìyàn tí ń ṣe inú dídùn sí ogun ká.
Riria te kirehe o nga kakaho, te huinga puru, me nga kuao kau a nga iwi, me te takahi i nga pihi hiriwa ki raro: whakamararatia nga iwi e ahuareka ana ki te whainga.
31 Àwọn ọmọ-aládé yóò wá láti Ejibiti; Etiopia yóò na ọwọ́ rẹ̀ sí Ọlọ́run.
E puta mai nga rangatira i Ihipa: meake hohoro te totoro o nga ringa o Etiopia ki te Atua.
32 Kọrin sí Ọlọ́run, ẹ̀yin ìjọba ayé, kọrin ìyìn sí Olúwa, (Sela)
Waiata ki te Atua, e nga rangatiratanga o te whenua: himene ki te Ariki: (Hera)
33 Sí ẹni tí ń gun ọ̀run dé ọ̀run àtijọ́ lókè, tó ń fọhùn rẹ̀, ohùn ńlá.
Ki a ia, ko tona hariata nei ko nga rangi o nga rangi, nonamata: na, ka puaki tona reo, he reo kaha.
34 Kéde agbára Ọlọ́run, ọláńlá rẹ̀ wà lórí Israẹli, tí agbára rẹ̀ wà lójú ọ̀run.
Waiho te kaha i te Atua, kei runga nei i a Iharaira tana mahi rangatira: kei nga kapua hoki tona kaha.
35 Ìwọ ní ẹ̀rù, Ọlọ́run, ní ibi mímọ́ rẹ; Ọlọ́run Israẹli fi agbára àti okun fún àwọn ènìyàn rẹ. Olùbùkún ní Ọlọ́run!
Ka wehingia koe, e te Atua, i roto i ou wahi tapu: ko te Atua o Iharaira te kaihomai i te kaha, i te mana, ki tona iwi. Whakapaingia te Atua.

< Psalms 68 >