< Psalms 67 >

1 Fún adarí orin. Pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn. Saamu. Orin. Kí Ọlọ́run kí ó ṣàánú fún wa kí ó sì bùkún fún wa, kí ó sì jẹ́ kí ojú rẹ̀ tàn yí wa ká,
Para el director del coro. Un salmo. Un canto. Para acompañamiento con instrumentos de cuerda. Que Dios sea misericordioso con nosotros y nos bendiga. Que hallemos gracia ante sus ojos. (Selah)
2 kí ọ̀nà rẹ le di mí mọ̀ ní ayé, ìgbàlà rẹ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.
Que todos los habitantes de la tierra conozcan tus caminos y tu salvación en medio de todos los pueblos.
3 Kí àwọn ènìyàn kí ó yìn ọ́, Ọlọ́run; kí gbogbo ènìyàn kí ó yìn ọ́!
Que todos te alaben, Dios. Sí, que todas las naciones te alaben.
4 Kí orílẹ̀-èdè kí ó yọ̀, kí ó sì kọrin fún ayọ̀, nítorí ìwọ fi òdodo darí àwọn ènìyàn, ìwọ sì jẹ ọba àwọn orílẹ̀-èdè ní ayé.
Que todos se alegren y canten de gozo porque tú haces juicio justo, y guías a todos los habitantes de la tierra. (Selah)
5 Kí àwọn ènìyàn kí ó yìn ọ́, Ọlọ́run; kí gbogbo ènìyàn kí ó yìn ọ́. (Sela)
Que todos te alaben, Dios. Sí, que todas las naciones te alaben.
6 Nígbà náà ní ilẹ̀ yóò mú ìkórè rẹ̀ wá, Ọlọ́run, Ọlọ́run wa, yóò bùkún fún wa.
La tierra ha producido su cosecha; y Dios, nuestro Dios, nos ha bendecido.
7 Ọlọ́run yóò bùkún fún wa, àti gbogbo òpin ilẹ̀ ayé yóò sì máa bẹ̀rù rẹ̀.
Dios nos bendecirá, y todos los habitantes de la tierra lo respetarán.

< Psalms 67 >