< Psalms 66 >

1 Fún adarí orin. Orin. Saamu. Ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọ́run, ẹ̀yin ilẹ̀ gbogbo!
Nǝƣmiqilǝrning bexiƣa tapxurulup, tarliⱪ sazlar bilǝn oⱪulsun dǝp, küy-nahxa: — Pütkül jaⱨan, huxalliⱪ bilǝn Hudaƣa tǝntǝnǝ ⱪilinglar!
2 Ẹ kọrin ọlá orúkọ rẹ̀; ẹ kọrin ìyìnsí i.
Uning namining uluƣluⱪini nahxa ⱪilip jakarlanglar, Uning mǝdⱨiyilirini xǝrǝplik ⱪilinglar!
3 Ẹ wí fún Ọlọ́run pé, “Ìwọ ti ní ẹ̀rù tó nínú iṣẹ́ rẹ! Nípa ọ̀pọ̀ agbára rẹ ni àwọn ọ̀tá rẹ yóò fi sìn ọ́.
Hudaƣa: «Sening ⱪilƣanliring nǝⱪǝdǝr ⱪorⱪunqluⱪtur! Ⱪudriting zor bolƣaq, Düxmǝnliring aldingda zǝiplixip tǝslim bolidu;
4 Gbogbo ayé ń wólẹ̀ fún ọ; wọn ń kọrin ìyìn sí ọ, wọ́n ń kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ.” (Sela)
Barliⱪ yǝr yüzidikilǝr Sanga sǝjdǝ ⱪilip, Seni küylǝp, nahxa eytixidu; Ular namingni küylǝp nahxa ⱪilip eytidu» — dǝnglar! (Selaⱨ)
5 Ẹ wá wo ohun tí Ọlọ́run ṣe, iṣẹ́ rẹ̀ ti ní ẹ̀rù tó sí àwọn ọmọ ènìyàn!
Kelinglar, Hudaning ⱪilƣanlirini kɵrünglar; Insan baliliri aldida ⱪilƣan karamǝtliri ⱪorⱪunqluⱪtur.
6 Ó yí òkun padà sí ilẹ̀ gbígbẹ, wọ́n fi ẹsẹ̀ rin inú omi kọjá, níbẹ̀ ni àwa yọ̀ nínú rẹ̀.
U dengizni ⱪuruⱪluⱪⱪa aylandurdi; [Əjdadlirimiz] dǝryadinmu piyadǝ ɵtti; Biz u yǝrdǝ uningdin hursǝn bolduⱪ.
7 Ó ń jẹ ọba títí láé nípa agbára rẹ̀, ojú rẹ̀ ń wo orílẹ̀-èdè kí àwọn ọlọ̀tẹ̀ má ṣe gbé ara wọn ga. (Sela)
U ⱪudriti bilǝn mǝnggü ⱨɵküm süridu; Uning kɵzliri ǝllǝrni kɵzitip turidu; Asiyliⱪ ⱪilƣuqilar mǝƣrurlanmisun! (Selaⱨ)
8 Ẹ yin Ọlọ́run wa, ẹ̀yin ènìyàn, jẹ́ kí a mú ni gbọ́ ohùn ìyìn rẹ̀;
I ⱪowmlar, Hudayimizƣa tǝxǝkkür-mǝdⱨiyǝ eytinglar; Uningƣa bolƣan mǝdⱨiyǝ-ⱨǝmdusanalarni yangritinglar!
9 Ó ti dá ààbò bo ẹ̀mí wa, kò sì jẹ́ kí ẹsẹ̀ wa kí ó yẹ̀.
U jenimizni ⱨayatliⱪ iqigǝ tikkǝn, Putlirimizni teyilduruxlarƣa yol ⱪoymaydu.
10 Nítorí ìwọ, Ọlọ́run, dán wa wò; ìwọ dán wa bí a tí ń dán fàdákà wò.
Qünki Sǝn, i Huda, bizni siniding; Kümüxni otta tawliƣandǝk bizni tawliding.
11 Ìwọ mú wa wá sínú ẹ̀wọ̀n o sì di ẹrù lé ẹ̀yìn wa.
Sǝn bizni torƣa qüxürdung; Belimizgǝ eƣir yükni yükliding.
12 Ìwọ mú àwọn ènìyàn gún wá ní orí àwa la iná àti omi kọjá ṣùgbọ́n ìwọ mú wa dé ibi ọ̀pọ̀.
Hǝⱪlǝrni beximizƣa mindürdüng; Biz ot wǝ kǝlkünni besip ɵttuⱪ; Sǝn ahir bizni kǝngriqilikkǝ qiⱪarding.
13 Èmi ó wá sí tẹmpili rẹ pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun, kí n sì mú ẹ̀jẹ́ mi ṣẹ sí ọ,
Mǝn kɵydürmǝ ⱪurbanliⱪlarni elip ɵyünggǝ kirǝy; Sanga ⱪilƣan ⱪǝsǝmlirimgǝ ǝmǝl ⱪilimǝn;
14 ẹ̀jẹ́ tí ètè mi jẹ́, tí ẹnu mi sì sọ nígbà tí mo wà nínú ìṣòro.
Bǝrⱨǝⱪ, beximƣa kün qüxkǝndǝ lǝwlirim qiⱪarƣan, Eƣizim eytⱪan wǝdilirimni ǝmǝlgǝ axurimǝn.
15 Èmi ó rú ẹbọ sísun ọlọ́ràá sí ọ, àti ẹbọ ọ̀rá àgbò; èmi ó rú akọ màlúù àti ewúrẹ́. (Sela)
Mǝn Sanga bordaⱪ mallarni kɵydürmǝ ⱪurbanliⱪ ⱪilip sunimǝn, Ⱪoqⱪarlarning yeƣini hux puritip kɵydürimǝn; Ɵküz wǝ ɵqkilǝrni ǝkilip sunimǝn. (Selaⱨ)
16 Ẹ wá gbọ́ gbogbo ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run; ẹ jẹ́ kí n sọ ohun tí ó ṣe fún mi.
Hudadin ǝymingüqi ⱨǝmminglar, kelinglar, ⱪulaⱪ selinglar! Uning mǝn üqün ⱪilƣan karamǝtlirini bayan ⱪilimǝn;
17 Mo fi ẹnu mi kígbe sókè sí i, ìyìn rẹ̀ wà ní ẹnu mi.
Aƣzim eqip uningƣa pǝryad kɵtürdüm, Uning uluƣluⱪini jakarliƣan mǝdⱨiyilǝr tilimda boldi.
18 Bí èmi bá gba ẹ̀ṣẹ̀ ní àyà mi, Olúwa kì yóò gbọ́ ohùn mi;
Kɵnglümdǝ gunaⱨni kɵzlǝp yürgǝn bolsam, Rǝb [duayimni] anglimiƣan bolatti.
19 ṣùgbọ́n Ọlọ́run gbọ́ nítòótọ́ ó ti gbọ́ ohùn mi nínú àdúrà.
Biraⱪ Huda anglidi; U duayimƣa ⱪulaⱪ saldi.
20 Ìyìn ni fún Ọlọ́run ẹni tí kò kọ àdúrà mi tàbí mú ìfẹ́ rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi!
Hudaƣa tǝxǝkkür-mǝdⱨiyǝ yaƣdurulsun! U mening duayimni yandurmidi, Ⱨǝm mǝndin ɵzgǝrmǝs muⱨǝbbitini elip kǝtmidi!

< Psalms 66 >