< Psalms 66 >

1 Fún adarí orin. Orin. Saamu. Ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọ́run, ẹ̀yin ilẹ̀ gbogbo!
Dziesma dziedātāju vadonim. Gavilējiet Dievam, visa zeme!
2 Ẹ kọrin ọlá orúkọ rẹ̀; ẹ kọrin ìyìnsí i.
Dziediet Viņa vārda godībai, teiciet Viņa godu.
3 Ẹ wí fún Ọlọ́run pé, “Ìwọ ti ní ẹ̀rù tó nínú iṣẹ́ rẹ! Nípa ọ̀pọ̀ agbára rẹ ni àwọn ọ̀tá rẹ yóò fi sìn ọ́.
Sakait uz Dievu: kāds bijājams Tu esi Savos darbos! Tavi ienaidnieki Tev padosies Tavas lielās varas pēc.
4 Gbogbo ayé ń wólẹ̀ fún ọ; wọn ń kọrin ìyìn sí ọ, wọ́n ń kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ.” (Sela)
Lai visa zeme Tevi pielūdz un Tev dzied, lai dzied Tavam Vārdam! (Sela)
5 Ẹ wá wo ohun tí Ọlọ́run ṣe, iṣẹ́ rẹ̀ ti ní ẹ̀rù tó sí àwọn ọmọ ènìyàn!
Nāciet un raugāt Dieva darbus. Viņš ir bijājams Savos darbos pie cilvēku bērniem.
6 Ó yí òkun padà sí ilẹ̀ gbígbẹ, wọ́n fi ẹsẹ̀ rin inú omi kọjá, níbẹ̀ ni àwa yọ̀ nínú rẹ̀.
Viņš pārvērta jūru par sausumu, kājām varēja iet caur upi; par to mēs iekš Viņa priecājamies.
7 Ó ń jẹ ọba títí láé nípa agbára rẹ̀, ojú rẹ̀ ń wo orílẹ̀-èdè kí àwọn ọlọ̀tẹ̀ má ṣe gbé ara wọn ga. (Sela)
Viņš valda mūžīgi ar Savu spēku, Viņa acis raugās uz tautām, Viņš atkāpējiem neļauj paaugstināties. (Sela)
8 Ẹ yin Ọlọ́run wa, ẹ̀yin ènìyàn, jẹ́ kí a mú ni gbọ́ ohùn ìyìn rẹ̀;
Teiciet mūsu Dievu, jūs tautas, liekat dzirdēt Viņa teikšanas slavu.
9 Ó ti dá ààbò bo ẹ̀mí wa, kò sì jẹ́ kí ẹsẹ̀ wa kí ó yẹ̀.
Viņš uztur dzīvas mūsu dvēseles un neliek slīdēt mūsu kājām.
10 Nítorí ìwọ, Ọlọ́run, dán wa wò; ìwọ dán wa bí a tí ń dán fàdákà wò.
Jo Tu, Dievs, mūs esi pārbaudījis; Tu mūs esi kausējis, kā sudrabu kausē.
11 Ìwọ mú wa wá sínú ẹ̀wọ̀n o sì di ẹrù lé ẹ̀yìn wa.
Tu mums esi licis iekrist valgos, uz mūsu muguru Tu esi licis grūtu nastu.
12 Ìwọ mú àwọn ènìyàn gún wá ní orí àwa la iná àti omi kọjá ṣùgbọ́n ìwọ mú wa dé ibi ọ̀pọ̀.
Tu cilvēkiem esi licis celties pār mūsu galvu; mēs bijām nākuši ugunī un ūdenī, bet Tu mūs esi izvedis pie atspirgšanas.
13 Èmi ó wá sí tẹmpili rẹ pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun, kí n sì mú ẹ̀jẹ́ mi ṣẹ sí ọ,
Es iešu Tavā namā ar dedzināmiem upuriem, es Tev maksāšu savu apsolījumu,
14 ẹ̀jẹ́ tí ètè mi jẹ́, tí ẹnu mi sì sọ nígbà tí mo wà nínú ìṣòro.
Uz ko manas lūpas ir atdarījušās, un ko mana mute runājusi, kad man bija bail.
15 Èmi ó rú ẹbọ sísun ọlọ́ràá sí ọ, àti ẹbọ ọ̀rá àgbò; èmi ó rú akọ màlúù àti ewúrẹ́. (Sela)
Es tev upurēšu taukus dedzināmos upurus ar kvēpināšanu no auniem; es Tev upurēšu vēršus ar āžiem. (Sela)
16 Ẹ wá gbọ́ gbogbo ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù Ọlọ́run; ẹ jẹ́ kí n sọ ohun tí ó ṣe fún mi.
Nāciet, klausāties visi, kas Dievu bīstaties: es jums izteikšu, ko Viņš darījis pie manas dvēseles.
17 Mo fi ẹnu mi kígbe sókè sí i, ìyìn rẹ̀ wà ní ẹnu mi.
Viņu es piesaucu ar savu muti, un Viņš tapa slavēts no manas mēles.
18 Bí èmi bá gba ẹ̀ṣẹ̀ ní àyà mi, Olúwa kì yóò gbọ́ ohùn mi;
Ja es netaisnību atrastu savā sirdī, tad Tas Kungs mani nebūtu klausījis.
19 ṣùgbọ́n Ọlọ́run gbọ́ nítòótọ́ ó ti gbọ́ ohùn mi nínú àdúrà.
Bet tiešām, Dievs ir klausījis, manas lūgšanas balsi Viņš ņēmis vērā.
20 Ìyìn ni fún Ọlọ́run ẹni tí kò kọ àdúrà mi tàbí mú ìfẹ́ rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi!
Slavēts Dievs, kas nav atmetis manu lūgšanu, nedz novērsis Savu žēlastību no manis.

< Psalms 66 >