< Psalms 65 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Orin. Ìyìn ń dúró dè ọ́, Ọlọ́run, ní Sioni; sí ọ ni a ó mú ẹ̀jẹ́ wa ṣẹ.
Gode! Ninia da Saione Moilai Bai Bagade amo ganodini Dima nodone sia: mu amola Dima ilegele sia: i liligi dafawane hamomu da defea.
2 Ìwọ tí ó ń gbọ́ àdúrà, gbogbo ènìyàn yóò sì wá sọ́dọ̀ rẹ.
Bai Di da ninia sia: ne gadosu amoma dabe adole iaha. Dunu fifi asi huluane da ilia wadela: i hou dawa: beba: le, Dima sisane fofada: musa: misunu. Ninia giadofasu da nini hasalasa. Be Di da ninima gogolema: ne olofosu iaha.
3 Ọ̀ràn àìṣedéédéé borí mi bí ó ṣe ti ìrékọjá wa ni! Ìwọ ni yóò wẹ̀ wọ́n nù kúrò.
4 Ìbùkún ni fún àwọn tí o yàn tí o mú wa láti máa gbé àgọ́ rẹ! A tẹ́ wá lọ́rùn pẹ̀lú ohun rere inú ilé rẹ, ti tẹmpili mímọ́ rẹ.
Nowa dunu amo Dia ilegele lale, Dia Hadigi Sogebi amo ganodini esaloma: ne oule maha, amo dunu da hahawane bagade gala. Ninia da Dia sema Debolo Diasu hahawane dogolegele liligi lai dagoiba: le, denesi ba: mu.
5 Ìwọ dá wa lóhùn pẹ̀lú ohun ìyanu ti òdodo, Ọlọ́run olùgbàlà wa, ẹni tí ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé gbogbo òpin ayé àti àwọn tí ó jìnnà nínú òkun,
Di da ninia sia: ne gadosu amoma dabe adole iasisia, ninia da ninima ha lai dunu ilima hasalasa. Amola Di da ninima gaga: ma: ne, hou noga: idafa hamosa. Dunu osobo bagadega fifi asi gala dialebe amola hano wayabo bagade la: idi fifi asi dialebe, huluane da Dima dafawaneyale dawa: sa
6 ìwọ tí ó dá òkè nípa agbára rẹ, tí odi ara rẹ ní àmùrè agbára,
Di da Dia gasa bagade hou amo olema: ne, Di goumi alelaloi amo ilia sogebi amogai bugisisu.
7 ẹni tí ó mú rírú omi òkun dákẹ́, ríru ariwo omi wọn, àti ìdágìrì àwọn ènìyàn.
Di da hano wayabo bagade ea gobe amola hano gafulubi bagade amo ouiya: lesisa. Amola fifi asi gala dunu ilia gugulubi amo ouiya: lesisa.
8 Àwọn tí ó ń gbé òkèrè bẹ̀rù, nítorí àmì rẹ wọ̀n-ọn-nì; ìwọ mú ìjáde òwúrọ̀ àti ti àṣálẹ́ yọ̀, ìwọ pè fún orin ayọ̀.
Osobo bagade fifi asi gala huluanedafa da Dia hahamoi liligi ba: beba: le, fofogadigili aligisa. Osobo bagade fifi asi gala huluane, la: idi bega: asili la: idi bega: , da Dia hahamoi amo ba: le, nodone wele sia: sa.
9 Ìwọ bẹ ayé wò, o sì bomirin; ìwọ mú un ọ̀rọ̀ púpọ̀. Odò Ọlọ́run kún fún omi láti pèsè ọkà fún àwọn ènìyàn, nítorí ibẹ̀ ni ìwọ ti yàn án.
Di da osobo bagade soge amoma gagagulasu hou olelema: ne, gibu iaha. Di da soge noga: le nasegagima: ne hamosa. Di da hano logo amo hanoga nabalesisa. Di da osobo amo hulu ha: i nasu bugili iasisa.
10 Ìwọ fi bomirin sí aporo rẹ̀ ìwọ tẹ́ ògúlùtu rẹ̀; ìwọ fi òjò mú ilẹ̀ rẹ̀ rọ̀, o sì bùkún ọ̀gbìn rẹ̀.
Di da agoane hamosa. Di da gibu bagadedafa amo osobo gidinaiga soga: sisa. Amola ilia da nanegai dagoi ba: sa. Di da osobo dasama: ne, sasafi gilisisa. Amasea, ha: i manu waha heda: be, amo noga: le heda: sa.
11 Ìwọ fi oore rẹ dé ọdún ní adé, ọ̀rá ń kán ní ipa ọ̀nà rẹ.
Dia hou noga: idafa da gamisu bagadedafa ninima iaha. Di da habi ahoasea, amogai da ha: i manu osea: idafa ba: mu.
12 Pápá tútù ní aginjù ń kan àwọn òkè kéékèèké fi ayọ̀ di ara wọn ní àmùrè.
Ohe fofole nasu soge huluane da ohe wa: i amoga nabai gala. Agolo la: idi soge amoga hahawane hou da nabai.
13 Agbo ẹran ni a fi wọ pápá tútù náà ní aṣọ; àfonífojì ni a fi ọkà bò mọ́lẹ̀, wọ́n hó fún ayọ̀, wọ́n ń kọrin pẹ̀lú.
Ohe fofole nasu soge da sibi amoga dedeboi dagoi. Fago da widi sagaiga nabai. Liligi huluanedafa da hahawaneba: le, ha: gi wele sia: sa amola gesami hea: lala.

< Psalms 65 >