< Psalms 61 >
1 Fún adarí orin. Ohun èlò orin olókùn. Ti Dafidi. Gbọ́ ẹkún mi, Ọlọ́run; tẹ́tí sí àdúrà mi.
Gode! Na Dima diniyabe amo nabima! Amola na Dima sia: ne gadobe nabima!
2 Láti òpin ayé wá ni èmi yóò pè ọ́, mo pè nígbà àyà mi ń ṣàárẹ̀; mú mi lọ sí ibi àpáta tí ó ga jù mí lọ.
Na da heawi amola fofagiba: le, na fifi lasu badiliadafa amogainini Dima wele sia: sa! Di da na wamoaligisu sogebi amoga oule masa.
3 Nítorí ìwọ ti jẹ́ ibi ààbò mi, ilé ìṣọ́ agbára àwọn ọ̀tá.
Bai Di da nama ha lai dunu, ilia na hasalasisa: besa: le gasa bagade gaga: sudafa gala.
4 Mo ń lépa láti máa gbé nínú àgọ́ rẹ títí láé kí n sì rí ààbò níbi ìyẹ́ apá rẹ.
Na esalabea gowane Dia Hadigi Sogebi ganodini esaloma: ma. Amola na da Dia ougiaha amo ganodini gaga: su ba: ma: ma.
5 Nítorí ìwọ ti gbọ́ àwọn ẹ̀jẹ́ mi, Ọlọ́run; Ìwọ ti fún mi ní ogún àwọn tí ó bẹ̀rù orúkọ rẹ.
Gode! Di da na sia: ilegebe amo nabi dagoi. Amola Dia da Dima nodone sia: be ili iabe, amo nama i dagoi.
6 Jẹ́ kí ẹ̀mí ọba kí ó gùn, ọdún rẹ̀ fún ìrandíran.
Osobo bagade hina da mae bogole gebewane esaloma: ma! Amola e da esaloma: ne ea ode ga gasigagama!
7 Kí ó máa jẹ ọba níwájú Ọlọ́run títí láé; pèsè àánú àti òtítọ́ rẹ tí yóò máa ṣe ìtọ́jú rẹ.
Gode! E da Dia midadi aligili, ea fi mae fisili eso huluane ouligilaloma: ma. Dia mae fisili asigidafa hou, amoga Dia e gaga: ma.
8 Nígbà náà ni èmi ó máa kọrin ìyìn sí orúkọ rẹ títí láé kí n san ẹ̀jẹ́ mi ní ojoojúmọ́.
Amaiba: le na da Dima hahabe asili daeya huluane imunusa: ilegei amo iaha, na da eso huluane Dima nodone gesami hea: lumu.