< Psalms 60 >

1 Fún adarí orin. Tí ohùn “Lílì ti Májẹ̀mú.” Miktamu ti Dafidi. Fún ìkọ́ni. Nígbà tí ó bá Aramu-Naharaimu àti Siria-Soba jà, àti nígbà tí Joabu yípadà tí ó sì pa ẹgbẹ̀rún méjìlá àwọn ará Edomu ní àfonífojì Iyọ̀. Ìwọ ti kọ̀ wá sílẹ̀, Ọlọ́run, ìwọ ti tú wa ká, ìwọ ti bínú nísinsin yìí, tún ara rẹ yípadà sí wa.
Neghmichilerning béshigha tapshurulup, «Guwahliq niluperi» dégen ahangda oqulsun dep, Dawut yazghan «Mixtam» küyi: — (Dawut Aram-Naharaim we Aram-Zobahdiki Suriyelikler bilen jeng qilghanda, [uning serdari bolghan] Yoab jengge qayta bérip, «Shor wadisi»da Édomdikilerdin on ikki ming eskerni qilichlighan chaghda yézilghan) I Xuda, Sen bizni chetke qaqting; Bizni pare-pare qiliwetting, Sen bizdin renjiding; Emdi bizni yéninggha qayturghin!
2 Ìwọ ti mú ilẹ̀ wárìrì, ìwọ ti fọ́ ọ; mú fífọ́ rẹ̀ bọ̀ sípò, nítorí tí ó mì.
Sen zéminni tewritip yériwetkeniding; Emdi uning bösüklirini saqaytqaysen; Chünki u deldengship ketti!
3 Ìwọ ti fi ìgbà ewu han àwọn ènìyàn rẹ; ìwọ fún wa ní wáìnì tí ó máa ń ta wá gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n.
Sen Öz xelqingge külpet-xarliqlarni körgüzdüng; Sen bizge alaqzadilikning sharabini ichküzdüng.
4 Àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, ní ìwọ fi ọ̀págun fún kí a lè fihàn nítorí òtítọ́. (Sela)
Sen Özüngdin eyminidighanlargha tugh tiklep bergensen; U heqiqetni ayan qilishqa kötürülidu. (Sélah)
5 Fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ gbà wá, kí o sì ràn wá lọ́wọ́, kí a lè gba àwọn tí o fẹ́ là.
Öz söygenliring nijatliq tépishi üchün, Ong qolung bilen qutquzghaysen, [Duayimni] ijabet qilghaysen.
6 Ọlọ́run ti sọ̀rọ̀ láti ibi mímọ́ rẹ̀: “Ní ayọ̀, èmi ó pọ Ṣekemu jáde èmi ó sì wọ́n àfonífojì Sukkoti.
Xuda Öz pak-muqeddeslikide shundaq dégen: — «Men tentene qilimen, Men Shekem diyarini bölüp bérimen, Sukkot wadisini [teqsim qilishqa] ölcheymen.
7 Tèmi ni Gileadi, tèmi sì ni Manase; Efraimu ni àṣíborí mi, Juda sì ni ọ̀pá àṣẹ mi.
Giléad Manga mensuptur, Manassehmu Manga mensuptur; Efraim bolsa béshimdiki dubulghamdur, Yehuda Méning emr-perman chiqarghuchimdur;
8 Moabu ní ìkòkò ìwẹsẹ̀ mi, lórí Edomu ní mo bọ́ bàtà mi sí; lórí Filistia ni mo kígbe ayọ̀.”
Moab Méning yuyunush jawurumdur; Édomgha choruqumni tashlaymen; Filistiye, Méning sewebimdin tentene qilinglar!»
9 Ta ni yóò mú mi wá sí ìlú olódi nì? Ta ni yóò tọ́ mí lọ sí Edomu?
Kim Méni bu mustehkem sheherge bashlap kirelisun? Kim Méni Édomgha élip baralisun?
10 Kì í ha ń ṣe ìwọ, Ọlọ́run, tí ó ti kọ̀ wá sílẹ̀ tí o kò sì bá ogun wa jáde mọ́?
I Xuda, Sen bizni rasttinla chetke qaqtingmu? Qoshunlirimiz bilen bille jengge chiqmamsen?
11 Fún wa ní ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn ọ̀tá, nítorí asán ni ìrànlọ́wọ́ ènìyàn.
Bizni zulumlardin qutulushqa yardemleshkeysen, Chünki insanning yardimi bikardur!
12 Nípa Ọlọ́run ni a óò ní ìṣẹ́gun, yóò sì tẹ àwọn ọ̀tá wa mọ́lẹ̀.
Xuda arqiliq biz choqum baturluq körsitimiz; Bizge zulum qilghuchilarni cheyligüchi del U Özidur!

< Psalms 60 >