< Psalms 60 >
1 Fún adarí orin. Tí ohùn “Lílì ti Májẹ̀mú.” Miktamu ti Dafidi. Fún ìkọ́ni. Nígbà tí ó bá Aramu-Naharaimu àti Siria-Soba jà, àti nígbà tí Joabu yípadà tí ó sì pa ẹgbẹ̀rún méjìlá àwọn ará Edomu ní àfonífojì Iyọ̀. Ìwọ ti kọ̀ wá sílẹ̀, Ọlọ́run, ìwọ ti tú wa ká, ìwọ ti bínú nísinsin yìí, tún ara rẹ yípadà sí wa.
Aw Khawssa, kaimih ve ni qoek khqi hawh tiksaw, kaimih ak khan awh nak kaw so hawh hy; nak kaw so hawh nawh - nim thawh tlaih lah!
2 Ìwọ ti mú ilẹ̀ wárìrì, ìwọ ti fọ́ ọ; mú fífọ́ rẹ̀ bọ̀ sípò, nítorí tí ó mì.
Nang ing qam ce thloek tiksaw can sak thulh hawh hyk ti; ak kqek khqi ve cawng tlaih lah, tlai nyk nyk hy.
3 Ìwọ ti fi ìgbà ewu han àwọn ènìyàn rẹ; ìwọ fún wa ní wáìnì tí ó máa ń ta wá gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n.
Nak thlangkhqi ce kawboet kyinaak ni huh sak khqi tiksaw; misur tui ni awk sak khqi nawh kami ceh am thym voel hy.
4 Àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, ní ìwọ fi ọ̀págun fún kí a lè fihàn nítorí òtítọ́. (Sela)
Cehlai, nang anik kqihkhqi aham taw, hizan ce hak zoek tiksaw li ce dan khoep hy.
5 Fi ọwọ́ ọ̀tún rẹ gbà wá, kí o sì ràn wá lọ́wọ́, kí a lè gba àwọn tí o fẹ́ là.
Nak tang kut ing ni hul khqi nawhtaw ni thaawng khqi lah, na lungnaak thlangkhqi loet na u seh.
6 Ọlọ́run ti sọ̀rọ̀ láti ibi mímọ́ rẹ̀: “Ní ayọ̀, èmi ó pọ Ṣekemu jáde èmi ó sì wọ́n àfonífojì Sukkoti.
Khawsa ing a hun ciim awhkawng: “Noengnaak ing Shechem ce cun kawng nyng saw Succoth tuikaw ce tah vang.
7 Tèmi ni Gileadi, tèmi sì ni Manase; Efraimu ni àṣíborí mi, Juda sì ni ọ̀pá àṣẹ mi.
Gilead ve kai a koe ni, Monasseh awm kai a koe ni; Ephraim ve ka thi lumyk na awm nawh, Judah ve ka sawnghqawl na awm hy.
8 Moabu ní ìkòkò ìwẹsẹ̀ mi, lórí Edomu ní mo bọ́ bàtà mi sí; lórí Filistia ni mo kígbe ayọ̀.”
Moab ve kang silh qunaak beihthuk na awm nawh, Edom ak khan awh ka khawmyk khawng nyng saw; Philistia qam khan awh noengnaak ing khy nyng,” tihy.
9 Ta ni yóò mú mi wá sí ìlú olódi nì? Ta ni yóò tọ́ mí lọ sí Edomu?
U ing nu khawk bau cak na anik ceh pyi kaw? U ing nu Edom na ani sawi kaw?
10 Kì í ha ń ṣe ìwọ, Ọlọ́run, tí ó ti kọ̀ wá sílẹ̀ tí o kò sì bá ogun wa jáde mọ́?
Aw Khawsa, nang ing ni qoek khqi nawh ka qaalkapkhqi mi am cet haih voel hyk ti ka ti my?
11 Fún wa ní ìrànlọ́wọ́ lórí àwọn ọ̀tá, nítorí asán ni ìrànlọ́wọ́ ènìyàn.
Qalkap tuknaak thai aham bawngnaak ni pe lah, kawtih thlanghqing ak bawngnaak taw a phi am awm hy.
12 Nípa Ọlọ́run ni a óò ní ìṣẹ́gun, yóò sì tẹ àwọn ọ̀tá wa mọ́lẹ̀.
Khawsa ing ni noengnaak ce ka mi huh hly, anih ing ni qaalkhqi ce a khaw ing a leh hly.