< Psalms 6 >

1 Fún adarí orin. Fún ohun èlò orin olókùn. Gẹ́gẹ́ bí ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi. Olúwa, má ṣe bá mi wí nínú ìbínú rẹ kí ìwọ má ṣe nà mí nínú gbígbóná ìrunú rẹ.
E IEHOVA, mai hoohewa mai oe ia'u me kou huhu; Mai hahau mai oe ia'u, me kou inaina nui.
2 Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń kú lọ; Olúwa, wò mí sán, nítorí egungun mi wà nínú ìnira.
E aloha mai oe ia'u, e Iehova, no ka mea, ua nawaliwali au; E Iehova, e lapaau mai oe ia'u, no ka mea, ua haalulu ko'u mau iwi.
3 Ọkàn mi wà nínú ìrora. Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa, yóò ti pẹ́ tó?
Ua pioloke loa ko'u uhane, Aka o oe, e Iehova, pehea la hoi ka loihi?
4 Yípadà, Olúwa, kí o sì gbà mí; gbà mí là nípa ìfẹ́ rẹ tí kì í ṣákì í.
E hoi mai, e Iehova, e hoopakele mai i ko'u uhane: E hoola mai oe ia'u no ka pono o kou aloha.
5 Ẹnikẹ́ni kò ni rántí rẹ nígbà tí ó bá kú. Ta ni yóò yìn ọ́ láti inú isà òkú? (Sheol h7585)
No ka mea, maloko o ka make aohe manao ia oe: Maloko o ka malu o ka make, owai la ka mea e hoolea aku ia oe? (Sheol h7585)
6 Agara ìkérora mi dá mi tán. Gbogbo òru ni mo wẹ ibùsùn mi pẹ̀lú ẹkún, mo sì fi omi rin ibùsùn mi pẹ̀lú omijé.
Ua luhi au i ko'u auwe ana; I ka po a pau i hoolana ai au i ko'u moena: Ua hoopulu au i ko'u wahi moe me ko'u waimaka.
7 Ojú mi di aláìlera pẹ̀lú ìbànújẹ́; wọ́n kùnà nítorí gbogbo ọ̀tá mi.
Ua pau e kuu maka no ko'u ehaeha; Ua kahiko e no ia no ko'u poe enemi a pau.
8 Kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣe iṣẹ́ ibi, nítorí Olúwa ti gbọ́ igbe mi.
E hele aku mai o'u aku nei, e ka poe hana ino a pau; No ka mea, ua lohe mai o Iehova i ka leo o ko'u uwe ana.
9 Olúwa ti gbọ́ ẹkún mi fún àánú; Olúwa ti gba àdúrà mi.
Ua lohe mai o Iehova i ko'u nonoi ana; E ae mai ana no o Iehova i ka'u pule.
10 Gbogbo àwọn ọ̀tá mi lójú yóò tì, wọn yóò sì dààmú; wọn yóò sì yípadà nínú ìtìjú àìròtẹ́lẹ̀.
E pioloke ko'u poe enemi a pau me ka haalulu loa; E hoi no lakou me ka hilahila koke.

< Psalms 6 >