< Psalms 6 >

1 Fún adarí orin. Fún ohun èlò orin olókùn. Gẹ́gẹ́ bí ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi. Olúwa, má ṣe bá mi wí nínú ìbínú rẹ kí ìwọ má ṣe nà mí nínú gbígbóná ìrunú rẹ.
Thaburi ya Daudi Wee Jehova, ndũkandũithie ũrĩ na marakara, o na kana ũũherithie ũrĩ na mangʼũrĩ.
2 Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń kú lọ; Olúwa, wò mí sán, nítorí egungun mi wà nínú ìnira.
Jehova, njiguĩra tha, nĩgũkorwo nĩthirĩtwo nĩ hinya; Wee Jehova honia, nĩgũkorwo mahĩndĩ makwa marĩ na ruo rũnene.
3 Ọkàn mi wà nínú ìrora. Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa, yóò ti pẹ́ tó?
O nayo ngoro yakwa ĩrĩ na ruo rũnene. Nĩ nginya rĩ, Wee Jehova, nĩ nginya rĩ?
4 Yípadà, Olúwa, kí o sì gbà mí; gbà mí là nípa ìfẹ́ rẹ tí kì í ṣákì í.
Wee Jehova, cooka, ũka ũũthare; honokia tondũ wa wendo waku ũrĩa ũtathiraga.
5 Ẹnikẹ́ni kò ni rántí rẹ nígbà tí ó bá kú. Ta ni yóò yìn ọ́ láti inú isà òkú? (Sheol h7585)
Gũtirĩ mũndũ ũngĩkũririkana arĩ mũkuũ. Nũũ ũkũgoocaga arĩ thĩinĩ wa mbĩrĩra? (Sheol h7585)
6 Agara ìkérora mi dá mi tán. Gbogbo òru ni mo wẹ ibùsùn mi pẹ̀lú ẹkún, mo sì fi omi rin ibùsùn mi pẹ̀lú omijé.
Niĩ ndĩ mũnogu mũno nĩ ũndũ wa gũcaaya; ũtukũ wothe njihũgagia ũrĩrĩ wakwa na kĩrĩro, na ngaconjoria gĩtĩ gĩakwa na maithori.
7 Ojú mi di aláìlera pẹ̀lú ìbànújẹ́; wọ́n kùnà nítorí gbogbo ọ̀tá mi.
Maitho makwa matirona wega nĩ ũndũ wa ihooru; nĩmaroora nĩ ũndũ wa thũ ciakwa ciothe.
8 Kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣe iṣẹ́ ibi, nítorí Olúwa ti gbọ́ igbe mi.
Njehererai inyuĩ arĩa othe mwĩkaga ũũru, nĩgũkorwo Jehova nĩaiguĩte kĩrĩro gĩakwa.
9 Olúwa ti gbọ́ ẹkún mi fún àánú; Olúwa ti gba àdúrà mi.
Jehova nĩaiguĩte ngĩmũthaitha anjiguĩre tha; Jehova nĩetĩkĩrĩte ihooya rĩakwa.
10 Gbogbo àwọn ọ̀tá mi lójú yóò tì, wọn yóò sì dààmú; wọn yóò sì yípadà nínú ìtìjú àìròtẹ́lẹ̀.
Thũ ciakwa ciothe nĩigaconoka na imake; igaacooka na thuutha o rĩmwe iconokete.

< Psalms 6 >