< Psalms 6 >
1 Fún adarí orin. Fún ohun èlò orin olókùn. Gẹ́gẹ́ bí ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi. Olúwa, má ṣe bá mi wí nínú ìbínú rẹ kí ìwọ má ṣe nà mí nínú gbígbóná ìrunú rẹ.
Aw Bawipa, kawso doena koeh ni zyi nawhtaw kaw tawknaak ing koeh ni toel.
2 Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń kú lọ; Olúwa, wò mí sán, nítorí egungun mi wà nínú ìnira.
Bawipa kak tha am awm saw nang ing nim qeen lah; Aw Bawipa ka quhkhqi tlo boeih hawh nawh, ni qoei sak lah.
3 Ọkàn mi wà nínú ìrora. Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa, yóò ti pẹ́ tó?
Ka hqingnaak ak tha hoet hawh hy. Aw Bawipa iqyt dy hly nu ve?
4 Yípadà, Olúwa, kí o sì gbà mí; gbà mí là nípa ìfẹ́ rẹ tí kì í ṣákì í.
Hlat law nawhtaw aw Bawipa kai ni hul lah; amak dyt thai na lungnaak ing ni hul lah.
5 Ẹnikẹ́ni kò ni rántí rẹ nígbà tí ó bá kú. Ta ni yóò yìn ọ́ láti inú isà òkú? (Sheol )
U ingawm a thih coeng awhtaw nang ce amni sim voel hy. U ing phyi khui awhkawng nang ce a nim kyihcah kaw? (Sheol )
6 Agara ìkérora mi dá mi tán. Gbogbo òru ni mo wẹ ibùsùn mi pẹ̀lú ẹkún, mo sì fi omi rin ibùsùn mi pẹ̀lú omijé.
Kang ko aih awh hoet hawh nyng, than zung kang kqang aih awh ka ih hun plym sak hawh nyng, ka ihkhun awm ka mikphli tui ing plym hawh hy.
7 Ojú mi di aláìlera pẹ̀lú ìbànújẹ́; wọ́n kùnà nítorí gbogbo ọ̀tá mi.
Kawset aih awh ka mik awm ak tha hoet khing nawh, ka qaalkhqi dawngawh ka mik awm am dai voel hy.
8 Kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣe iṣẹ́ ibi, nítorí Olúwa ti gbọ́ igbe mi.
Nangmih them che ak saikhqi, ka ven awhkawng cet hlah uh, kawtih Bawipa ing kang kqangnaak awi za hawh hy.
9 Olúwa ti gbọ́ ẹkún mi fún àánú; Olúwa ti gba àdúrà mi.
Qeennaak thoeh nawh kak khynaak awi ce Bawipa ing za nawh; kak cykcahnaak awi ce Bawipa ing do hy.
10 Gbogbo àwọn ọ̀tá mi lójú yóò tì, wọn yóò sì dààmú; wọn yóò sì yípadà nínú ìtìjú àìròtẹ́lẹ̀.
Ka qaalkhqi boeih ing a mingngaih kyi kawmsaw chah phyi kawm uh; chah phyih doena ami huna hlat tlaih kawm uh.