< Psalms 6 >

1 Fún adarí orin. Fún ohun èlò orin olókùn. Gẹ́gẹ́ bí ti ṣeminiti. Saamu ti Dafidi. Olúwa, má ṣe bá mi wí nínú ìbínú rẹ kí ìwọ má ṣe nà mí nínú gbígbóná ìrunú rẹ.
Hina Gode! Nama Di mae ougima amola gagabole mae sia: ma. Nama dia ougi amoga se mae ima.
2 Ṣàánú fún mi, Olúwa, nítorí èmi ń kú lọ; Olúwa, wò mí sán, nítorí egungun mi wà nínú ìnira.
Hina Gode! Na da gufia: ne gala: i galebe. Nama asigima! Na da: i da gasa hamedei galebe. Di nama gasa ima.
3 Ọkàn mi wà nínú ìrora. Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa, yóò ti pẹ́ tó?
Na da: i huluane da se nabala Hina Gode! Di da habowali ouesalu na fidima: bela: ?
4 Yípadà, Olúwa, kí o sì gbà mí; gbà mí là nípa ìfẹ́ rẹ tí kì í ṣákì í.
Hina Gode! Fidila misa! Di da asigiba: le, na bogosa: besa: le, Dia na gaga: ma.
5 Ẹnikẹ́ni kò ni rántí rẹ nígbà tí ó bá kú. Ta ni yóò yìn ọ́ láti inú isà òkú? (Sheol h7585)
Osobo bagade fi bogosu sogebi amo ganodini ilia da Di hame dawa: sa. Amogawi, Dima nodomu da hamedei. (Sheol h7585)
6 Agara ìkérora mi dá mi tán. Gbogbo òru ni mo wẹ ibùsùn mi pẹ̀lú ẹkún, mo sì fi omi rin ibùsùn mi pẹ̀lú omijé.
Na da da: i dioi bagade nababeba: le, gasa hame galebe. Gasi huluane, na wibi fa: i da na si hano amoga nanegai ba: sa. Na busafugulu amola da na si hano amoga nanegai ba: sa.
7 Ojú mi di aláìlera pẹ̀lú ìbànújẹ́; wọ́n kùnà nítorí gbogbo ọ̀tá mi.
Nama ha lai da nama se bagade iabeba: le, na da bagadewane disa. Na si da fofaiba: le, ba: mu gogolei.
8 Kúrò lọ́dọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin tí ń ṣe iṣẹ́ ibi, nítorí Olúwa ti gbọ́ igbe mi.
Dilia wadela: i hou hamosu dunu! Nama mae gadenena misa. Hina Gode da na disu naba.
9 Olúwa ti gbọ́ ẹkún mi fún àánú; Olúwa ti gba àdúrà mi.
Gode da na fidima: ne dibi naba amola na sia: ne gadobe bu alofele imunu.
10 Gbogbo àwọn ọ̀tá mi lójú yóò tì, wọn yóò sì dààmú; wọn yóò sì yípadà nínú ìtìjú àìròtẹ́lẹ̀.
Nama ha lai ilia da dafamuba: le bagadewane gogosiamu. Di da ili sefasimuba: le, ilia da hedolowane gogolele dafugili hobeamu.

< Psalms 6 >