< Psalms 58 >
1 Fún adarí orin. Tí ohùn “Má ṣe parun.” Ti Dafidi. Miktamu. Ẹ̀yin ha ń sọ òdodo nítòótọ́ ẹ̀yin ìjọ ènìyàn? Ǹjẹ́ ẹ̀yin ń ṣe ìdájọ́ tí ó ṣe títọ́ ẹ̀yìn ọmọ ènìyàn?
Thaburi ya Daudi Inyuĩ aathani aya-rĩ, ti-itherũ nĩmwaragia maũndũ ma kĩhooto? Nĩmũtuagĩra andũ ciira ũrĩa kwagĩrĩire na kĩhooto?
2 Bẹ́ẹ̀ kọ́, nínú ọkàn yín ẹ̀yìn ń gbèrò àìṣòdodo, ọwọ́ yín sì tú ìwà ipá jáde ni ayé.
Aca, ngoro-inĩ cianyu mũthugundaga maũndũ matarĩ ma kĩhooto, na moko manyu mageeka maũndũ ma kũruta haaro gũkũ thĩ.
3 Ní inú ìyá wọn wá ni ènìyàn búburú tí ṣìnà, lójúkan náà tí a ti bí wọn, wọn a máa ṣèké.
O kuuma gũciarwo andũ arĩa aaganu nĩmahĩtagia njĩra; matũũraga marĩ imaramari kuuma gũciarwo, na maaragia maheeni.
4 Oró wọn dàbí oró ejò, wọn dàbí adití ejò paramọ́lẹ̀ tí ó di ara rẹ̀ ni etí,
Ũrũrũ wao nĩ ta ũrũrũ wa nyoka, ũhaana ta thumu wa nduĩra ĩthingĩte matũ mayo,
5 tí kò ní gbọ́ ìpè àwọn atunilójú, bí ó ti wù kí ó máa fi ọgbọ́n ṣe ìtujú tó.
ĩrĩa ĩtangĩigua rwĩmbo rwa mũmĩthuuthĩri, o na angĩkorwo aramĩthuuthĩra arĩ na ũũgĩ mũnene atĩa.
6 Ká eyín ẹnu wọn, Ọlọ́run; ní ẹnu wọn, ká ọ̀gàn àwọn ọmọ kìnnìún, Olúwa.
Wee Ngai, unanga magego marĩa marĩ tũnua twao; Wee Jehova, munya mĩthangiri ya mĩrũũthi ĩyo!
7 Jẹ́ kí wọn parẹ́ bí omi tó ń sàn lọ; nígbà tí ó bá fa ọfà rẹ̀, kí ọ̀kọ̀ wọn kí ó ṣẹ́.
Nĩmabuĩrie o ta maaĩ marĩa mathereraga makabuĩria; rĩrĩa magereka ũta-rĩ, mĩguĩ yao nĩĩkoragwo ĩrĩ mĩtuuhu.
8 Jẹ́ kí wọn rí bí ìgbín tí rẹ̀ dànù tí ó sì ṣègbé bí ọmọ tí oṣù rẹ̀ kò pé, kí wọn má ṣe rí oòrùn.
Marotuĩka ta ndinoho ĩrĩa ĩtwekaga o ĩgĩthiiaga, matuĩke ta kĩhuno kĩrĩa gĩtoonaga riũa.
9 Kí ìkòkò yín kí ó tó mọ ìgbóná ẹ̀gún; bóyá ní tútù tàbí ní gbígbẹ, yóò fi ìjì gbá wọn lọ.
Andũ arĩa aaganu makeeherio narua, gũkĩra ũrĩa nyũngũ cianyu ingĩhiũhio nĩ mwaki wa mĩigua, ĩrĩ mĩigũ kana ĩrĩ mĩũmũ.
10 Olódodo yóò yọ̀ nígbà a bá ń gbẹ̀san wọn, nígbà tí wọn bá wẹ ẹsẹ̀ wọn nínú ẹ̀jẹ̀ ènìyàn búburú.
Andũ arĩa athingu nĩmagakena maarĩhĩrio, rĩrĩa magathambia nyarĩrĩ ciao thakame-inĩ ya arĩa aaganu.
11 Àwọn ènìyàn yóò wí pé, “Lóòtítọ́ èrè àwọn ń bẹ fún olódodo; lóòtítọ́ òun ni Ọlọ́run tí ń ṣe ìdájọ́ ní ayé.”
Hĩndĩ ĩyo andũ nĩmakoiga atĩrĩ, “Ti-itherũ nĩ kũrĩ na irĩhi rĩa arĩa athingu; ti-itherũ nĩ kũrĩ Ngai ũrĩa ũtuagĩra andũ a thĩ ciira.”