< Psalms 57 >
1 Fún adarí orin. Ní ohùn “Má ṣe parun.” Ti Dafidi. Miktamu. Nígbà tí ó sá níwájú Saulu lọ sínú ihò òkúta. Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, ṣàánú fún mi, nítorí nínú rẹ ni ààbò ọkàn mí wà. Èmi o fi ààbò mí sí ibi ìyẹ́ apá rẹ títí tí ewu yóò fi kọjá lọ.
Ki te tino kaiwhakatangi. Aratakiti. He Mikitama. Na Rawiri, i tona rerenga i a Haora i a ia nei i roto i te ana. Tohungia ahau, e te Atua, tohungia ahau, e whakawhirinaki ana hoki toku wairua ki a koe: ae, ka piri ahau ki raro ki te taumarumarut anga o ou pakau, kia pahemo ra ano enei mate.
2 Mo kígbe sókè sí Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo jùlọ, sí Ọlọ́run tó ń pa májẹ̀mú rẹ̀ mọ́ fún mi.
Ka karanga ahau ki te Atua, ki te Runga Rawa, ki te Atua e oti ai aku mea katoa.
3 Òun yóò ránṣẹ́ láti ọ̀run wá, yóò sì gbà mí, bí ẹni tí ń fẹ́ gbé mi mì tilẹ̀ ń kẹ́gàn mi. Ọlọ́run yóò rán àánú rẹ̀ àti òdodo rẹ̀ jáde.
Ka unga mai e ia he kaiwhakaora moku i te rangi, ina tawai te tangata e mea ana kia horomia ahau; (Hera) ka unga mai e te Atua tana mahi tohu me tona pono.
4 Mo wà ní àárín àwọn kìnnìún; mo dùbúlẹ̀ ni abẹ́ àwọn ẹ̀dá búburú, àwọn ènìyàn tí eyín wọn dàbí ọ̀kọ̀ àti ọfà ẹni tí ahọ́n rẹ̀ jẹ́ idà mímú.
Kei waenganui toku wairua i nga raiona: e takoto ana ahau i waenganui i te hunga e kaia ana e te ahi; i nga tama hoki a te tangata, he tao nei o ratou niho, he pere, he hoari koi ano o ratou arero.
5 Kí a yìn ọ́ Ọlọ́run, ju ọ̀run lọ, kí ògo rẹ kò ju ti gbogbo ayé lọ.
Kia whakanuia koe, e te Atua, ki runga ake i nga rangi: hei runga atu i te whenua katoa tou kororia.
6 Wọ́n ti ta àwọ̀n sílẹ̀ fún ẹsẹ̀ mi: a tẹ orí ọkàn mi ba nínú ìtìjú, wọ́n gbẹ́ kòtò sí ọ̀nà mi: ṣùgbọ́n wọ́n ti jì síbẹ̀ fún ara wọn.
Kua whakatakotoria e ratou he kupenga mo oku takahanga, kua piko toku wairua: kua keria e ratou he poka ki toku aroaro, a taka iho ko ratou ano ki roto. (Hera)
7 Ọkàn mi ti múra Ọlọ́run; ọkàn mi ti múra, èmi ó kọrin, èmi ó si máa kọrin ìyìn.
Pamau tonu toku ngakau, e te Atua, pumau tonu toku ngakau: ka waiata ahau, ae, ka himene ahau.
8 Jí, ìwọ ọkàn mi! Jí, ohun orin èlò àti dùùrù! Èmi tìkára mi, yóò sì jí ní kùtùkùtù.
E ara, e toku kororia; e ara, e te hatere, e te hapa: ka ara wawe ano ahau.
9 Èmi ó máa yìn ọ́, Olúwa, láàrín àwọn orílẹ̀-èdè; èmi ó máa kọrin sí ọ láàrín àwọn ènìyàn.
Ka whakamoemiti ahau ki a koe, e te Ariki, i waenganui i nga iwi; ka himene ki a koe i waenganui i nga tauiwi.
10 Nítorí títóbi ní ìfẹ́ rẹ, tí ó dé ọ̀run; òtítọ́ rẹ tàn dé àwọsánmọ̀.
He nui hoki tau mahi tohu, a tutuki noa ki nga rangi, me tou pono a tutuki noa ki nga kapua.
11 Gbígbéga ni ọ́, Ọlọ́run, ju àwọn ọ̀run lọ; kí ògo rẹ kí ó ju gbogbo ayé lọ.
Kia whakanuia koe, e te Atua, ki runga i nga rangi: hei runga i te whenua katoa tou kororia.