< Psalms 56 >

1 Fún adarí orin. Ti ohùn “Àdàbà lórí Óákù òkè réré.” Ti Dafidi. Miktamu. Nígbà tí àwọn ará Filistini ka mọ́ ní Gati. Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, nítorí àwọn ènìyàn ń fi ìgbónára lépa mi; ní gbogbo ọjọ́ ni wọn ń kọjú ìjà sí mi, wọn ń ni mi lára.
Gode! Nama asigiba: le, fidima! Bai nama ha lai dunu da nama doagala: sa. Ilia da eso huluane, nama se iaha.
2 Àwọn ọ̀tá mi ń lé mi ní gbogbo ọjọ́, àwọn ènìyàn ń kọjú ìjà sí mi nínú ìgbéraga wọn.
Hahabe asili daeya mae fisili, ilia da nama doagala: sa. Nama gegebe dunu da bagohamedafa.
3 Nígbà tí ẹ̀rù bà ń bà mí, èmi o gbẹ́kẹ̀lé ọ.
Hina Gode Bagadedafa! Na da beda: i galea, na da Dima dafawaneyale dawa: mu.
4 Nínú Ọlọ́run èmi yóò máa yìn ọ̀rọ̀ rẹ, nínú Ọlọ́run ni ìgbẹ́kẹ̀lé mi; ẹ̀rù kì yóò bà mí kí ni ẹran-ara lè ṣe sí mi?
Na da Godema dafawaneyale dawa: beba: le, hame beda: sa. Na da Ea hamomusa: ilegei amo ba: beba: le, Ema nodosa. Be osobo bagade dunu da na wadela: lesimu hame dawa:
5 Wọn ń yí ọ̀rọ̀ mí ní gbogbo ọjọ́, wọn ń gbèrò nígbà gbogbo láti ṣe mí níbi.
Nama ha lai dunu da hahabe asili daeya amo na se nabima: ne, bidi hamosu hamonana. Ilia da esoha huluane mae fisili, na se nabima: ne ilegelala.
6 Wọn kó ara wọn jọ, wọ́n ba. Wọ́n ń ṣọ́ ìgbésẹ̀ mi wọn ń làkàkà láti gba ẹ̀mí mi.
Ilia da wamoaligisu sogebi amo ganodini gilisili, na hamobe huluane ba: lala. Ilia da na medole legemu hanai.
7 San ẹ̀san iṣẹ́ búburú wọ́n fún wọn; ní ìbínú rẹ, Ọlọ́run, wọ́ àwọn ènìyàn náà bọ́ sílẹ̀.
Gode! Ilia wadela: i hou hamobeba: le, ilima se dabe ima. Dia amo dunuma ougili hasalima.
8 Kọ ẹkún mi sílẹ̀; kó omijé mi sí ìgò rẹ, wọ́n kò ha sí nínú ìkọ̀sílẹ̀ rẹ bí?
Na se nabasu huluane, amo Di dawa: Di da na disa si hano amo idili dedena sa: i diala. Amo da Dia buga ganodini dedei diala.
9 Nígbà náà ni àwọn ọ̀tá mi yóò pẹ̀yìndà nígbà tí mo bá pè fún ìrànlọ́wọ́ nípa èyí ni mo mọ̀ pé Ọlọ́run ń bẹ fún mi.
Esoha amoga na da Dima wele sia: sea, nama ha lai dunu da sinidigili, sefasi dagoi ba: mu. Amo na dawa: Bai Gode da namagai gala.
10 Nínú Ọlọ́run, ẹni tí mo yìn ọ̀rọ̀ rẹ̀ nínú Olúwa, ẹni tí mo yin ọ̀rọ̀ rẹ̀,
E da Hina Godedafa amola na da Ea sia: i ilegei amoma nodosa.
11 nínú Ọlọ́run ni ìgbẹ́kẹ̀lé mi: ẹ̀rù kì yóò bà mí. Kí ni ènìyàn lè ṣe sí mi?
Na da Ema dafawaneyale dawa: sa. Amaiba: le, na da hame beda: mu! Amola osobo bagade dunu da na wadela: lesimu hamedeidafa.
12 Mo jẹ́ ẹ̀jẹ́ lábẹ́ rẹ Ọlọ́run: èmi o mú ìyìn mi wá fún ọ.
Gode! Na da Dima imunusa: ilegei liligi amo Dima dafawane imunu. Na da Dia nodoma: ne gobele salasu amo Dima imunu.
13 Nítorí ìwọ tí gbà mí lọ́wọ́ ikú àti ẹsẹ̀ mi lọ́wọ́ ìṣubú, kí èmí lè máa rìn níwájú Ọlọ́run ní ìmọ́lẹ̀ àwọn alààyè.
Bai Dia da na mae bogoma: ne, na gaga: i dagoi. Amola nama ha lai ilia na mae hasalima: ne hamoi. Amaiba: le na da Gode Ea midadi, hadigi amo da esalebe dunuma diga: be, amo ganodini lala.

< Psalms 56 >