< Psalms 55 >

1 Fún adarí orin. Pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn. Maskili ti Dafidi. Fi etí sí àdúrà mi, Ọlọ́run, má ṣe fi ojú pa ẹ̀bẹ̀ mi rẹ́:
Gode! Na sia: ne gadobe nabima! Na Dima edegebe amo mae yolesima!
2 gbọ́ mi kí o sì dá mi lóhùn. Èrò mi ń dà mí láàmú, èmi sì ń pariwo.
Na sia: nabima amola na sia: be goea bu dabe adole ima. Na da gufia: ne hamoiba: le, gasa hame gala.
3 Sí ohùn àwọn ọ̀tá ni, nítorí igbe àwọn ènìyàn búburú; nítorí wọ́n mú ìjìyà wá sórí mi, wọ́n sì kẹ́gàn mi nínú ìbínú wọn.
Nama ha lai da nama magagibiba: le, na da bagade beda: i. Wadela: i hamosu dunu da na banenesibiba: le, na da gala: la sa: i dagoi. Ilia da nama bidi hamosu gaguli maha. Ilia da nama ougi gala amola na higasa.
4 Ọkàn mi wà nínú ìrora pẹ̀lú; ẹ̀rù ikú kọjú ìjà sí mi.
Na da baligili beda: i. Na da bogosa: besa: le bagade beda: i, amola banenesi dagoi ba: sa.
5 Ìbẹ̀rù àti ìwárìrì wa sí ara mi; ìbẹ̀rù ti bò mí mọ́lẹ̀.
Na da beda: ga yagugulala. Na da beda: ne se nabasu amoga gagulaligi.
6 Èmi sọ pé, “Èmi ìbá ní ìyẹ́ bí àdàbà! Èmi ìbá fò lọ kí n sì sinmi.
Na da ougia hamoi ‘dafe’ sio agoai ganeya: be. Amai ganiaba, na da amoga hagili asili, helefimu soge hogola: loba.
7 Èmi ìbá sálọ, jìnnà réré, kí ń sì dúró sí aginjù;
Na da hagili badiliadafa hafoga: i sogega fifi lasu hamona: noba.
8 èmi ìbá yára lọ́ si ibùgbé mi ní ibi ààbò, jìnnà kúrò nínú ìjì àti ẹ̀fúùfù líle.”
Na da fo amola mulu gulubagebe amoga fasa: besa: le, ougiha wamoaligimusa: hedolowane fimusa: hogola: loba.
9 Da àwọn ẹni búburú láàmú, Olúwa, da ahọ́n wọn rú, nítorí èmi rí ìwà agbára àti ìjà ní ìlú náà.
Hina Gode! Nama ha lai dunu ilia sia: mu liligi huluane ededenanesima! Na da moilai bai bagade ganodini, gegesu amola bidi hamosu bagadewane ba: lala.
10 Ọ̀sán àti òru ni wọ́n fi ń rìn gbogbo odi kiri; ìwà ìkà àti èébú wà láàrín rẹ̀.
Amo bidi hamosu da bagadeba: le, gasia amola hayoga fedege agoane moilai bai bagade sisiga: le disisa.
11 Ìwà búburú ń bẹ ní àárín rẹ̀; ẹ̀tàn àti èké kò kúrò ní ìgboro rẹ̀.
Gugunufinisi hou da soge huluane ganodini ba: sa. Moilai bai bagade logo da banenesisu hou amola fedele wamolasu amoga nabai gala.
12 Tí ọ̀tá bá tàbùkù mi, èmi yóò fi ara mọ́ ọn; tí ọ̀tá bá gbé ara rẹ̀ ga sí mi, èmi ìbá sá pamọ́ fún un.
Be nama ha lai dunu da nama lasogole sia: sa ganiaba, na da hame da: i dione dawa: la: loba. Amola nama dabesu dunu da nama hidale sia: sa ganiaba, na da ema hobeale wamoaligimu dawa: la: loba.
13 Ṣùgbọ́n tí ó bá ṣe ìwọ, ọkùnrin bí ẹgbẹ́ mi, ẹlẹgbẹ́ mi, àti ọ̀rẹ́ tí ó súnmọ́ mi,
Be di, na dogolegei sama disu da nama lasogole amola hidale sia: nana.
14 pẹ̀lú ẹni tí èmi ti jẹ ìgbádùn adùn ìdàpọ̀, bí a ṣe ń rìn pẹ̀lú àwùjọ ní ilé Ọlọ́run.
Ani da musa: gilisili osodogone sia: dasu. Ania da Debolo ganodini Godema nodone sia: ne gadosu.
15 Kí ikú kí ó dé bá wọn, kí wọn ó lọ láààyè sí isà òkú, jẹ́ kí wọn ó sọ̀kalẹ̀ sí ibojì pẹ̀lú ìpayà, nítorí tí ìwà búburú ń bẹ ní ibùjókòó wọn, àti nínú wọn. (Sheol h7585)
Nama ha lai dunu ilia da ilia bogosu eso mae doaga: le, bogomu da defea. Ilia da esaleawane, bogoi sogega gudu sa: imu da defea. Wadela: i hou da ilia diasu gaguli gagai amola ilia dogo amo ganodini dialebe ba: sa. (Sheol h7585)
16 Ṣùgbọ́n èmi pe Ọlọ́run; Olúwa yóò sì gbà mí.
Be na da Hina Godema, na fidima: ne wele sia: sa. Amasea, E da na gaga: mu.
17 Ní alẹ́, ní òwúrọ̀ àti ní ọ̀sán èmi sọkún jáde nínú ìpọ́njú, o sì gbọ́ ohùn mi.
Hahabe amola esomogoa amola gasia, na egasu sia: amola na gogonomosu da Ema heda: sa. Amola E da na sia: nabimu.
18 Ó rà mí padà láìléwu kúrò nínú ogun tí ó dìde sí mi, nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó dìde sí mi.
Na da nama ha lai dunu bagohame ilima gegena ahoa. Be Hina Gode da na gaga: iwane bu goeguda: oule misunu.
19 Ọlọ́run yóò gbọ́, yóò sì pọ́n wọn lójú àní, ẹni tí ó ti jókòó láti ìgbàanì (Sela) nítorí tí wọn kò ní àyípadà, tí wọn kò sì bẹ̀rù Ọlọ́run.
Gode da musa: hemoneganini, ouligisa mana wali doaga: i. E da na sia: nabimu amola nama ha lai dunu ili hasalimu. Bai ilia da afadenemu higasa amola Godema hame beda: sa.
20 Ọ̀rẹ́ mi yìí ti dalẹ̀ èmi ọ̀rẹ́ rẹ̀; ó ti ba májẹ̀mú rẹ̀ jẹ́.
Na musa: dogolegei sama da ea sama ili amo doagala: le, amola e da ea ilelegele sia: i amo fi dagoi.
21 Ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ̀ kúnná ju òrí-àmọ́, ṣùgbọ́n ogun wà ni àyà rẹ̀; ọ̀rọ̀ rẹ̀ fẹ́lẹ́ ju òróró lọ, ṣùgbọ́n idà fífàyọ ní wọn.
Ea sia: da ha: i manu gugui defele nabi. Be ea dogo ganodini, ougili higasu fawane galu. Ea sia: da susuligi noga: i defele nabi. Be amo sia: da gegesu gobihei agesoi defele, fa: ginisi.
22 Gbé ẹrù rẹ lọ sí ọ̀dọ̀ Olúwa yóò sì mú ọ dúró; òun kò ní jẹ́ kí olódodo ṣubú.
Dilia! Dilia da: i dioi amola se nabasu huluane amo Godema yolesima. Amasea, E da dili gaga: mu. Ea fidibiba: le, moloidafa dunu da hamedafa hasali dagoi ba: sa.
23 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni yóò mu àwọn ọ̀tá mi wá sí ihò ìparun; àwọn ẹni tí òǹgbẹ ẹ̀jẹ̀ ń gbẹ àti ẹni ẹ̀tàn, kì yóò gbé ààbọ̀ ọjọ́ wọn. Ṣùgbọ́n fún èmi, èmi gbẹ́kẹ̀lé ọ.
Be Di, Gode! Di da amo fane legesu dunu amola wamolasu dunu amo fane legemu. Ilia esalusu dogoa hame doaga: i galeawane, Di da ili bogoi uli dogosu sogebi amoga oule masunu. Be amomane na da Dima fawane dafawaneyale dawa: mu.

< Psalms 55 >