< Psalms 54 >

1 Fún adarí orin. Pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn. Maskili ti Dafidi. Nígbà tí àwọn ará Sifi lọ sọ fún Saulu pé, “Dafidi sá pamọ́ sọ́dọ̀ wa?” Gbà mí, Ọlọ́run nípa orúkọ rẹ: dá mi láre nípa agbára rẹ.
Dāvida mācības dziesma. Dziedātāju vadonim, uz koklēm. Kad Zifieši nāca un Saulam sacīja: vai Dāvids pie mums nav paslēpies? Ak Dievs atpestī mani caur Savu vārdu un nes man tiesu caur Savu varu.
2 Gbọ́ àdúrà mi, Ọlọ́run; fi etí sí ọ̀rọ̀ ẹnu mi.
Ak Dievs, klausi manu lūgšanu, liec vērā, ko mana mute runā.
3 Àwọn agbéraga àlejò dìde sí mí. Àwọn aninilára sì ń wá mi láti pa, àwọn ẹni tí kò ka Ọlọ́run sí ní ojú wọn.
Jo svešinieki ceļas pret mani, un briesmīgi ļaudis meklē manu dvēseli; tie netur Dievu priekš savām acīm. (Sela)
4 Kíyèsi i Ọlọ́run ni olùrànlọ́wọ́ mi; Olúwa ní ẹni tí ó mú mi dúró, pa wọ́n run nínú òtítọ́ rẹ.
Redzi, Dievs man ir par palīgu; Tas Kungs ir tas, kas manu dvēseli uztur.
5 Jẹ́ kí ibi padà sẹ́yìn sí àwọn tí ń sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ sí mi; pa wọ́n run nínú òtítọ́ rẹ.
Viņš maksās to ļaunumu maniem nicinātājiem; izdeldē tos pēc Tavas uzticības.
6 Èmí yóò rú ẹbọ àtinúwá sí ọ, èmi yóò yin orúkọ rẹ, Olúwa, nítorí tí ó dára.
Tad es Tev upurēšu ar labu prātu, es pateikšos, Kungs, Tavam Vārdam, ka tas ir tik labs.
7 Nítorí tí ó yọ mí kúrò nínú ibi gbogbo ojú mi ti wo ìṣẹ́gun lórí ọ̀tá mi.
Jo Viņš mani izglābis no visām bēdām, ka mana acs ar prieku uzlūko manus ienaidniekus.

< Psalms 54 >