< Psalms 54 >

1 Fún adarí orin. Pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn. Maskili ti Dafidi. Nígbà tí àwọn ará Sifi lọ sọ fún Saulu pé, “Dafidi sá pamọ́ sọ́dọ̀ wa?” Gbà mí, Ọlọ́run nípa orúkọ rẹ: dá mi láre nípa agbára rẹ.
Thaburi ya Daudi Wee Ngai, honokia nĩ ũndũ wa rĩĩtwa rĩaku; ndĩhĩria na hinya waku.
2 Gbọ́ àdúrà mi, Ọlọ́run; fi etí sí ọ̀rọ̀ ẹnu mi.
Wee Ngai, igua ihooya rĩakwa; thikĩrĩria ciugo cia kanua gakwa.
3 Àwọn agbéraga àlejò dìde sí mí. Àwọn aninilára sì ń wá mi láti pa, àwọn ẹni tí kò ka Ọlọ́run sí ní ojú wọn.
Andũ ageni nĩmanjũkĩrĩire; nao andũ matarĩ tha nĩmaracaria muoyo wakwa, o andũ acio matarũmbũyagia Ngai.
4 Kíyèsi i Ọlọ́run ni olùrànlọ́wọ́ mi; Olúwa ní ẹni tí ó mú mi dúró, pa wọ́n run nínú òtítọ́ rẹ.
Ti-itherũ Ngai nĩwe ũteithio wakwa; Mwathani nĩwe ũndiiragĩrĩra.
5 Jẹ́ kí ibi padà sẹ́yìn sí àwọn tí ń sọ̀rọ̀ ìbàjẹ́ sí mi; pa wọ́n run nínú òtítọ́ rẹ.
Cookereria andũ arĩa manjambagia ũũru wao; Wee maniine nĩ ũndũ wa wĩhokeku waku.
6 Èmí yóò rú ẹbọ àtinúwá sí ọ, èmi yóò yin orúkọ rẹ, Olúwa, nítorí tí ó dára.
Nĩngũkũrutĩra igongona rĩa kwĩyendera; nĩngũgooca rĩĩtwa rĩaku, Wee Jehova, tondũ nĩ rĩega.
7 Nítorí tí ó yọ mí kúrò nínú ibi gbogbo ojú mi ti wo ìṣẹ́gun lórí ọ̀tá mi.
Nĩgũkorwo nĩahonoketie mathĩĩna-inĩ makwa mothe, na maitho makwa nĩmeyoneire gũtoorio gwa thũ ciakwa.

< Psalms 54 >