< Psalms 53 >

1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí mahalati. Maskili ti Dafidi. Aṣiwèrè wí ní ọkàn rẹ̀ pé, “Ọlọ́run kò sí.” Wọ́n bàjẹ́, gbogbo ọ̀nà wọn sì burú; kò sì ṣí ẹnìkan tí ń ṣe rere.
Načelniku godbe na piščal; pesem Davidova ukovita. Nespametni govori v srci svojem: Ni ga Boga; pohujšujejo in ostudno krivico doprinašajo, ni ga, da bi delal dobro.
2 Ọlọ́run bojú wo ilẹ̀ láti ọ̀run sórí àwọn ọmọ ènìyàn, láti wò bóyá ẹnìkan wà, tí ó ní òye, tí ó sì ń wá Ọlọ́run.
Bog z neba gleda dol na sinove človeške, da bi videl, je li kateri, da bi bil razumen, da bi iskal Boga.
3 Gbogbo ènìyàn tí ó ti yí padà, wọ́n ti parapọ̀ di ìbàjẹ́; kò sí ẹnìkan tí ó ń ṣe rere, kò sí ẹnìkan.
Vsak je odstopil, izpridili so se vsi vkup: ni ga, da bi delal dobro, ne enega samega.
4 Ṣé àwọn oníṣẹ́ búburú kò ní ìmọ̀? Àwọn ẹni tí ń jẹ ènìyàn mi, bí ẹni jẹun tí wọn kò sì pe Ọlọ́run?
Ali si niso v svesti, kateri delajo krivico, ker žró ljudstvo moje kruh jedóč, ne kličejo Boga?
5 Níbẹ̀ ni ìwọ gbé wà ní ìbẹ̀rù ńlá níbi tí ẹ̀rù kò gbé sí, nítorí Ọlọ́run tí fọ́n egungun àwọn tí ó dó tì ọ́ ká; ìwọ tí dójútì wọ́n, nítorí Ọlọ́run ti kẹ́gàn wọn.
Tam se preplašijo od groze, kjer ni groze; ker Bog razsuje kosti vsakega, kateri ima šatorišče svoje zoper tebe; osramotiš jih, ker Bog jih zameta.
6 Ìgbàlà Israẹli ìbá jáde wá láti Sioni! Nígbà tí Ọlọ́run bá mú ohun ìní àwọn ènìyàn rẹ̀ padà, jẹ́ kí Jakọbu yọ̀ kí inú Israẹli sì máa dùn!
O kdó naj dá blaginjo sè Sijona Izraelu? Ko bode nazaj peljal iz sužnjosti ljudstva svojega krdelo, veselil se bode Jakob, radoval se Izrael.

< Psalms 53 >