< Psalms 53 >
1 Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí mahalati. Maskili ti Dafidi. Aṣiwèrè wí ní ọkàn rẹ̀ pé, “Ọlọ́run kò sí.” Wọ́n bàjẹ́, gbogbo ọ̀nà wọn sì burú; kò sì ṣí ẹnìkan tí ń ṣe rere.
U A olelo ka aia iloko o kona naau, Aohe Akua. Ua hewa pu lakou, ua hana hoi lakou i na mea e inainaia; Aohe mea i hana ma ka pono.
2 Ọlọ́run bojú wo ilẹ̀ láti ọ̀run sórí àwọn ọmọ ènìyàn, láti wò bóyá ẹnìkan wà, tí ó ní òye, tí ó sì ń wá Ọlọ́run.
Nana mai la ke Akua mai luna mai o ka lani i na keiki a kanaka, I ike mai i kekahi mea naauao paha e imi ana i ke Akua.
3 Gbogbo ènìyàn tí ó ti yí padà, wọ́n ti parapọ̀ di ìbàjẹ́; kò sí ẹnìkan tí ó ń ṣe rere, kò sí ẹnìkan.
Pau lakou i ka hoi hope pu; Pau pu lakou i ka haumia; Aohe mea hana maikai, aole loa hookahi.
4 Ṣé àwọn oníṣẹ́ búburú kò ní ìmọ̀? Àwọn ẹni tí ń jẹ ènìyàn mi, bí ẹni jẹun tí wọn kò sì pe Ọlọ́run?
Aole anei naauao iki ko ka poe hana hewa? Ka poe e pau ai ko'u poe kanaka i ka aiia, E like me ko lakou ai ana i ka berena: Aole lakou i kahea i ke Akua.
5 Níbẹ̀ ni ìwọ gbé wà ní ìbẹ̀rù ńlá níbi tí ẹ̀rù kò gbé sí, nítorí Ọlọ́run tí fọ́n egungun àwọn tí ó dó tì ọ́ ká; ìwọ tí dójútì wọ́n, nítorí Ọlọ́run ti kẹ́gàn wọn.
Malaila makau loa lakou ma kahi makau ole; No ka mea, ua hoohelelei ke Akua i na iwi o ka mea hoomoana ku e ia oe: Ua hoohilahila oe ia lakou, No ka mea, ua hoowahawaha mai ke Akua ia lakou.
6 Ìgbàlà Israẹli ìbá jáde wá láti Sioni! Nígbà tí Ọlọ́run bá mú ohun ìní àwọn ènìyàn rẹ̀ padà, jẹ́ kí Jakọbu yọ̀ kí inú Israẹli sì máa dùn!
Nawai la ke ola e haawi mai i ka Iseraela mailoko mai o Ziona? Aia hoihoi mai ke Akua i ke pio ana o kona poe kanaka, E hauoli no o Iakoba, e olioli no hoi o Iseraela.