< Psalms 51 >

1 Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Nígbà ti wòlíì Natani tọ wá, lẹ́yìn tí Dafidi dá ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè rẹ̀ pẹ̀lú Batṣeba. Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, gẹ́gẹ́ bí ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ àánú rẹ̀ kí o sì pa gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi rẹ́.
Kathutkung: Devit Oe Cathut, na pahren han ngai e patetlah na pahren haw. Kapap ni teh kahawi e na lungmanae dawkvah, kâtapoenae hah na tha pouh haw.
2 Wẹ gbogbo àìṣedéédéé mi nù kúrò kí o sì wẹ̀ mi mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi!
Ka sakpayon e pueng kathoungcalah na pâsu pouh haw. Ka yonnae dawk hoi na thoung sak haw.
3 Nítorí mo mọ̀ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi, nígbà gbogbo ni ẹ̀ṣẹ̀ mi wà níwájú mi.
Kâtapoenae hah ka panue toe. Ka yonnae teh pou ka pouk.
4 Sí ọ, ìwọ nìkan ṣoṣo, ni mo dẹ́ṣẹ̀ sí ni mo sì ṣe búburú níwájú rẹ̀, kí a lè dá ọ láre nígbà tí ìwọ bá ń sọ̀rọ̀, kí o sì le wà láìlẹ́bi, nígbà tí ìwọ bá ń ṣe ìdájọ́.
Nang taranlahoi nang koe roeroe ka yon toe. Na mithmu vah hawihoehnae ka sak toe. Ka kong na dei toteh atang doeh. Lawk na ceng toteh, toun han awm hoeh.
5 Nítòótọ́, nínú ẹ̀ṣẹ̀ ni a ti bí mi, nínú ẹ̀ṣẹ̀ ni ìyá mí sì lóyún mi.
Kai teh payonnae lahoi khe e lah ka o teh, anu ni yon hoi doeh na vawn toe.
6 Nítòótọ́ ìwọ fẹ́ òtítọ́ ní inú; ìwọ kọ́ mi ní ọgbọ́n ní ìhà ìkọ̀kọ̀.
Lungthin kalan e hah na ngai dawkvah, ka lungthin thung lungangnae hah na cangkhai haw.
7 Wẹ̀ mí pẹ̀lú ewé hísópù, èmi yóò sì mọ́; fọ̀ mí, èmi yóò sì funfun ju yìnyín lọ.
Dingsala hoi na hui haw, ka thoung han. Na pâsu haw tadamtui patetlah ka pangaw han.
8 Jẹ́ kí n gbọ́ ayọ̀ àti inú dídùn; jẹ́ kí gbogbo egungun tí ìwọ ti run kí ó máa yọ̀.
Na khoe tangcoung e hrunaw konawm nahanlah, konawmnae hoi lunghawinae lawk na thaisak haw.
9 Pa ojú rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi kí o sì pa gbogbo àwọn àìṣedéédéé mi rẹ́.
Ka yonnae dawk hoi na minhmai hrawk nateh, ka yonnae pueng hah na takhoe pouh haw.
10 Dá ọkàn mímọ́ sí inú mi, Ọlọ́run, kí o sì tún ẹ̀mí dídúró ṣinṣin ṣe sínú mi.
Oe Cathut, ka thungvah lungthin kathoung bout sak nateh, kai dawk kacakpounge muitha hah bout roung sak haw.
11 Má ṣe jù mi nù kúrò níwájú rẹ, kí o má ṣe gba Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ lọ́wọ́ mi.
Nang koehoi na pâlei hanh lah a. Na Kathoung Muitha teh kai koehoi na lat pouh hanh.
12 Mú ayọ̀ ìgbàlà rẹ tọ̀ mí wá, kí o sì fún mi ní ẹ̀mí ìfẹ́, tí yóò mú mi dúró.
Na rungngangnae dawk konawmnae hah bout na poe haw. Hringpasoungnae na Muitha hoi na kuen haw.
13 Nígbà náà ni èmi yóò máa kọ́ àwọn olùrékọjá ní ọ̀nà rẹ, àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóò sì yí padà sí ọ.
Hottelah, kâtapoenaw hah na lamthung ka cangkhai vaiteh, tamikayonnaw teh nang koe a kâthung awh han.
14 Gbà mí kúrò lọ́wọ́ ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀, Ọlọ́run, ìwọ Ọlọ́run ìgbàlà mi, ahọ́n mi yóò sì máa kọrin òdodo rẹ kíkan.
Oe Cathut, kaie rungngangnae Cathut, tami thei e yon hoi na hlout sak haw. Na lannae hah ka lai ni kacaipounglah la a sak han.
15 Olúwa, ṣí mi ní ètè mi gbogbo, àti ẹnu mi yóò sì máa kéde ìyìn rẹ.
Oe BAWIPA, ka pahni heh paawng nateh, ka pahni ni na pholen han.
16 Nítorí ìwọ kò ní inú dídùn sí ẹbọ, tí èmi kò bá mú wá; Ìwọ kò ní inú dídùn sí ọrẹ ẹbọ sísun.
Bangkongtetpawiteh, thuengnae hah na ngai e nahoeh. Hoehpawiteh, yo na poe han doeh toe. Hmaisawi thuengnae dawk hai na lungyouknae awm hoeh.
17 Ẹbọ Ọlọ́run ni ìròbìnújẹ́ ọkàn ìròbìnújẹ́ àti ìrora àyà.
Cathut ngai e patetlah thuengnae hateh, muitha rek e hah doeh. Lungthin rek laihoi pankângai e heh, Oe Cathut, banglahai noutna laipalah na awm mahoeh.
18 Ṣe rere ní dídùn inú rẹ sí Sioni, ṣe rere; tún odi Jerusalẹmu mọ.
Zion vah na ngai e hawinae hah sak haw, Jerusalem rapan hah kangdout sak haw.
19 Nígbà náà ni inú rẹ yóò dùn sí ẹbọ òdodo, pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun àti ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ọrẹ ẹbọ sísun, nígbà náà ni wọn yóò fi akọ màlúù rú ẹbọ lórí pẹpẹ rẹ.
Hottelah hoiyah, lannae thuengnae hoi hmaisawi thuengnae hoi takbuem hmaisawi thuengnae dawk na lunghawi vaiteh, na thuengnae khoungroe van vah, maitotan hah a thueng awh han.

< Psalms 51 >