< Psalms 50 >
1 Saamu ti Asafu. Olúwa, Ọlọ́run alágbára, sọ̀rọ̀ kí o sì pe ayé jọ láti ìlà-oòrùn títí dé ìwọ̀ rẹ̀.
Hina Gode Bagadedafa da sia: sa. E da osobo bagade fifi asi gala huluanedafa, gusudili asili guma: dini, ilima wele sia: sa.
2 Láti Sioni wá, pípé ni ẹwà, Ọlọ́run tí ń tan ìmọ́lẹ̀
Saione Moilai Bai Bagade da isisima: goi ida: iwanedafa. Amoganini, Gode Ea hadigi da diga: sa.
3 Ọlọ́run ń bọ̀, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò dákẹ́, iná yóò máa jó níwájú rẹ̀, àti ní àyíká rẹ̀ ni ẹ̀fúùfù líle yóò ti máa jà ká.
Ninia Gode da manebe. Be E da ouiya: lewane hame maha. Gegemoi lalu da E bisili ahoa. Amola mulu bagade da E sisiga: le disisa.
4 Yóò sì pe àwọn ọ̀run láti òkè wá jọ àti ayé, kí o le máa ṣe ìdárò àwọn ènìyàn rẹ̀.
E da Ea fi dunuma fofada: musa: , mu amola osobo bagade ba: su hou hamoma: ne elama ilegele wele sia: sa.
5 “Kó àwọn ènìyàn mímọ́ jọ fún mi àwọn tí wọn fi ẹbọ dá májẹ̀mú fún mi.”
E da amane sia: sa, “Na mae fisili fa: no bobogesu dunu, ilia da Nama gobele salawane gousa: su hamoi, amo huluane Nama gegedole oule misa!”
6 Àwọn ọ̀run yóò sì sọ̀rọ̀ òdodo rẹ̀, nítorí Ọlọ́run fúnra rẹ̀ ni onídàájọ́.
Mu da amane sisia: laha, “Gode da moloidafa amola Hisu da fofada: su dunudafa!”
7 “Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ènìyàn mi, èmi yóò si sọ̀rọ̀, ìwọ Israẹli, èmi yóò jẹ́rìí sí ọ: èmi ní Ọlọ́run, àní Ọlọ́run rẹ.
Hina Gode da amane sia: sa, “Na fi dunu! Nabima! Na da sia: mu! Na da dilia, Isala: ili dunu dilima diwaneya udidimu. Na da Gode! Na da dilia Gode!
8 Èmi kí yóò bá ọ wí nítorí àwọn ìrúbọ rẹ, tàbí ọrẹ ẹbọ sísun rẹ, èyí tí ó wà níwájú mi ní ìgbà gbogbo.
Dilia da mae fisili gobei gobele salasu Nama gaguli maha. Amoga, Na da dilima hame gagabole sia: sa.
9 Èmí kò fẹ́ kí ó mú akọ màlúù láti inú ilé tí o kọ́ fún un, tàbí kí o mú òbúkọ láti inú agbo ẹran rẹ̀
Be bulamagau gawali dilia afugi amoga lai amola goudi dilia goudi fofoi wa: i amoga lai, amo Na da hame hanasa.
10 nítorí gbogbo ẹran igbó ni tèmi àti ẹran ọ̀sìn lórí ẹgbẹ̀rún òkè.
Bai ohe huluane iwilaga esala da Na: fawane. Amola bulamagau agolo osea: idafa amoga esala da Na: fawane.
11 Èmi mọ gbogbo ẹyẹ ní orí àwọn òkè ńlá àti gbogbo ẹ̀dá alààyè tí ó wà ní orí ilẹ̀ ni tèmi.
Sigua sio huluanedafa da Na: fawane. Amola liligi huluane amo da moifufu sogega esalebe, da Na: fawane.
12 Bí ebi tilẹ̀ ń pa mí, èmi kì yóò sọ fún ọ, nítorí ayé ni tèmi àti ohun gbogbo tí ó wa ní inú rẹ̀.
Na da ha: i ganiaba, Na da dilima hame adola: loba. Bai osobo bagade amola liligi huluane amo ganodini gala da Na: fawane.
13 Ǹjẹ́ èmi yóò ha jẹ ẹran akọ màlúù tàbí mú ẹ̀jẹ̀ òbúkọ?
Na da bulamagau gawali ilia hu nabela: ? Na da goudi ilia maga: me nabela: ? Hame naha!
14 “Rú ẹbọ ọpẹ́ sí Ọlọ́run, kí o sì san ẹ̀jẹ́ rẹ fún Ọ̀gá-ògo.
Be dilia Godema gobele salasu hou dafawanedafa da Ema nodone sia: su. Amola Hina Bagadedafa Ema dilia imunu ilegei amo huluane defele Ema ima.
15 Kí o sì pè mí ní ọjọ́ ìpọ́njú, èmi yóò gbà ọ́, ìwọ yóò sì bu ọlá fún mi.”
Bidi hamosu da dilima doaga: sea, Nama fidima: ne wele sia: ma! Amasea, Na da dili gaga: mu. Amola dilia da Nama nodomu.”
16 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run sọ fún àwọn, ènìyàn búburú: “Kí ní ẹ̀tọ́ tí o ní tí ìwọ fi ń tún àwọn ìlànà mi sọ, tàbí tí ìwọ sì ń sọ májẹ̀mú mi ní ẹnu rẹ?
Be Gode da wadela: i hamosu dunu ilima amane sia: sa, “Dilia da abuliba: le Na hamoma: ne sia: i amo sia: daha? Dilia da abuliba: le Na gousa: su hamoi, amoga fada: i sia: dahabela: ?
17 Ìwọ kórìíra àṣẹ mi, ìwọ sì ṣá ọ̀rọ̀ mí tì sí apá kan.
Na gagabole sia: amo dilia higasa. Amola Na hamoma: ne sia: i higale, nabawane hame hamosa.
18 Nígbà tí ìwọ rí olè, ìwọ dára pọ̀ mọ́ ọn, ìwọ sì da ara rẹ dé àwọn alágbèrè.
Dilia da nowa wamolasu dunu ba: sea, amo dilia dogolegei sama agoane hamosa. Amola dilia da inia uda adole lasu dunu ilima gilisisa.
19 Ìwọ lo ẹnu rẹ fún aburú, ìwọ sì ń fi ahọ́n rẹ pète ẹ̀tàn.
Dilia da eso huluane wadela: i hou fuligala: ma: ne sia: musa: momagele esala. Amola hedolowane ogogole sia: daha.
20 Ní ìgbà gbogbo ìwọ ń sọ̀rọ̀ sí arákùnrin rẹ, ìwọ sì ń ba orúkọ ọmọ ìyá rẹ jẹ́.
Dilia da diolalalidafa ilima diwaneya udidima: ne momagele esala. Amola ilia giadofai hogole, hedolowane olelesa.
21 Àwọn nǹkan wọ̀nyí ni ìwọ ti ṣe, mo sì dákẹ́; ìwọ rò pé mo jẹ́ irú kan náà bí ìrẹ, ṣùgbọ́n èmi yóò bá ọ wí, èmi yóò sì fi ẹ̀sùn kàn ọ́ ní ojú ara rẹ.
Amo hou huluane, dilia da hamoi dagoi. Be Na da dilima hame sia: i. Amaiba: le, dilia da Na hou da dilia hou defele dawa: i. Be wali Na da dilima gagabole sia: sa. Dilia wadela: le hamoi, amo Na da dili noga: le dawa: ma: ne, dilima olelesa.
22 “Ǹjẹ́ ìwọ ro èyí wò, ẹ̀yin tí ó gbàgbé Ọlọ́run. Bí bẹ́ẹ̀ kọ́ èmi yóò fa yin ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, láìsí ẹni tí yóò gbà yin sílẹ̀.
Dilia Nama hame dawa: digisu dunu! Na sia: nabima! Dilia da Na sia: hame nabasea, Na da dili wadela: lesimu. Amola dilia da gaga: su dunu hame ba: mu.
23 Ẹni tí ó ba ní ẹbọ ọrẹ-ọpẹ́ bu ọlá fún mi; kí ó sì tún ọ̀nà rẹ̀ ṣe, kí èmi kí ó le fi ìgbàlà Ọlọ́run hàn án.”
Nama gobele salasu houdafa da Nama nodone sia: ne gadosu hou, amo fawane. Amola nowa da Na sia: nabawane hamosea, Na da amo dunu dafawane gaga: mu.”