< Psalms 5 >

1 Fún adarí orin. Fún ohun èlò orin fífọn. Saamu ti Dafidi. Fi etí sí ọ̀rọ̀ mi, Olúwa, kíyèsi àròyé mi.
Nǝƣmiqilǝrning bexiƣa tapxurulup, nǝylǝr bilǝn oⱪulsun dǝp, Dawut yazƣan küy: — Mening sɵzlirimgǝ ⱪulaⱪ salƣaysǝn, i Pǝrwǝrdigar, Mening aⱨlirimƣa kɵngül bɵlgǝysǝn.
2 Fi etí sílẹ̀ sí igbe mi fún ìrànlọ́wọ́, ọba mi àti Ọlọ́run mi, nítorí ìwọ ni mo gba àdúrà sí.
Kɵtürgǝn pǝryadlirimni angla, mening Padixaⱨim, mening Hudayim, Qünki sangila dua ⱪilimǝn.
3 Ní òwúrọ̀, Olúwa, ìwọ yóò gbọ́ ohùn mi; ní òwúrọ̀, èmi yóò gbé ẹ̀bẹ̀ mi sí iwájú rẹ̀ èmi yóò sì dúró ní ìrètí.
I Pǝrwǝrdigar, sǝⱨǝrdǝ Sǝn awazimni anglaysǝn; Mǝn sǝⱨǝrdǝ ɵzümni Sanga ⱪaritimǝn, Yuⱪiriƣa kɵz tikimǝn.
4 Nítorí ìwọ kì í ṣe Ọlọ́run tí ó ní inú dídùn sí búburú; bẹ́ẹ̀ ni ẹni ibi kò le è bá ọ gbé.
Qünki Sǝn rǝzilliktin ⱨuzur alƣuqi ilaⱨ ǝmǝsdursǝn; Yamanliⱪ ⱨǝrgiz Sǝn bilǝn billǝ turmaydu.
5 Àwọn agbéraga kò le è dúró níwájú rẹ̀. Ìwọ kórìíra gbogbo àwọn aṣebi;
Poqi-tǝkǝbburlar kɵzüng aldida turalmaydu; Ⱪǝbiⱨlik ⱪilƣuqilarning ⱨǝmmisi Sanga yirginqliktur.
6 ìwọ yóò pa àwọn tí ń ṣe èké run. Apani àti ẹni ẹ̀tàn ènìyàn ni Olúwa yóò kórìíra.
Yalƣan sɵzligüqilǝrning ⱨǝmmisini ⱨalak ⱪilisǝn; Pǝrwǝrdigar ⱪanhor, aldamqi kixilǝrgǝ nǝprǝt ⱪilur.
7 Ṣùgbọ́n èmi, nípa títóbi àánú rẹ̀, èmi yóò wá sínú ilé rẹ̀; ní tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ ni èmi yóò tẹríba sí ìhà tẹmpili mímọ́ rẹ̀.
Biraⱪ mǝn bolsam, meⱨri-xǝpⱪitingning kǝngriqilikidin ɵyünggǝ kirimǝn; Sanga bolƣan ǝyminixtin muⱪǝddǝs ibadǝthanangƣa ⱪarap sǝjdǝ ⱪilimǝn;
8 Tọ́ mi, Olúwa, nínú òdodo rẹ, nítorí àwọn ọ̀tá mi, mú ọ̀nà rẹ tọ́ níwájú mi.
Meni ɵq kɵrgǝnlǝr tüpǝylidin Ɵz ⱨǝⱪⱪaniyliⱪing bilǝn meni yetǝkligǝysǝn, i Pǝrwǝrdigar; Yolungni aldimda tüz ⱪilƣin.
9 Kò sí ọ̀rọ̀ kan ní ẹnu wọn tí a lè gbàgbọ́; ọkàn wọn kún fún ìparun. Ọ̀nà ọ̀fun wọn ni isà òkú tí ó ṣí sílẹ̀; pẹ̀lú ahọ́n wọn ni wọ́n ń sọ ẹ̀tàn.
Qünki ularning aƣzida ⱨeqⱪandaⱪ sǝmimiylik yoⱪtur; Ularning iqki dunyasi bolsa pasiⱪliⱪtur, Ularning galliri eqilƣan ⱪǝbridǝk sesiⱪtur, Ular tili bilǝn huxamǝt ⱪiliwatidu.
10 Dá wọn lẹ́bi Ọlọ́run! Jẹ́ kí rìkíṣí wọn jẹ́ ìṣubú wọn. Lé wọn jáde nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀ṣẹ̀ wọn, nítorí wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí ọ.
Ularning gunaⱨini bekitkǝysǝn, i Huda; Ular ɵz pilanliri bilǝn ɵzliri mollaⱪ atsun; Ularni ɵzlirining nurƣunliƣan itaǝtsizlikliri bilǝn ⱨǝydǝp qiⱪarƣaysǝn; Qünki ular Sanga asiyliⱪ ⱪildi.
11 Ṣùgbọ́n, jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ó sádi ọ́ kí ó yọ̀; jẹ kí wọn máa kọrin fún ayọ̀ títí. Tan ààbò rẹ sórí wọn, àti àwọn tí ó fẹ́ràn orúkọ rẹ yóò máa yọ̀ nínú rẹ.
Xundaⱪ ⱪilƣanda Sanga tayanƣanlarning ⱨǝmmisi xadlinidu; Ular mǝnggü xadliⱪ bilǝn tǝntǝnǝ ⱪilidu; Sǝn ularni ⱪoƣdaysǝn; Sening namingni sɵygǝnlǝr seningdin yayraydu.
12 Dájúdájú, Olúwa, ìwọ bùkún olódodo; ìwọ fi ojúrere rẹ yí wọn ká bí asà.
Qünki Sǝn, i Pǝrwǝrdigar, ⱨǝⱪⱪaniy adǝmgǝ bǝht ata ⱪilisǝn; Uni xapaiting bilǝn ⱪalⱪan kǝbi oraysǝn.

< Psalms 5 >