< Psalms 5 >

1 Fún adarí orin. Fún ohun èlò orin fífọn. Saamu ti Dafidi. Fi etí sí ọ̀rọ̀ mi, Olúwa, kíyèsi àròyé mi.
Neghmichilerning béshigha tapshurulup, neyler bilen oqulsun dep, Dawut yazghan küy: — Méning sözlirimge qulaq salghaysen, i Perwerdigar, Méning ahlirimgha köngül bölgeysen.
2 Fi etí sílẹ̀ sí igbe mi fún ìrànlọ́wọ́, ọba mi àti Ọlọ́run mi, nítorí ìwọ ni mo gba àdúrà sí.
Kötürgen peryadlirimni angla, méning Padishahim, méning Xudayim, Chünki sangila dua qilimen.
3 Ní òwúrọ̀, Olúwa, ìwọ yóò gbọ́ ohùn mi; ní òwúrọ̀, èmi yóò gbé ẹ̀bẹ̀ mi sí iwájú rẹ̀ èmi yóò sì dúró ní ìrètí.
I Perwerdigar, seherde Sen awazimni anglaysen; Men seherde özümni Sanga qaritimen, Yuqirigha köz tikimen.
4 Nítorí ìwọ kì í ṣe Ọlọ́run tí ó ní inú dídùn sí búburú; bẹ́ẹ̀ ni ẹni ibi kò le è bá ọ gbé.
Chünki Sen rezilliktin huzur alghuchi ilah emesdursen; Yamanliq hergiz Sen bilen bille turmaydu.
5 Àwọn agbéraga kò le è dúró níwájú rẹ̀. Ìwọ kórìíra gbogbo àwọn aṣebi;
Pochi-tekebburlar közüng aldida turalmaydu; Qebihlik qilghuchilarning hemmisi Sanga yirginchliktur.
6 ìwọ yóò pa àwọn tí ń ṣe èké run. Apani àti ẹni ẹ̀tàn ènìyàn ni Olúwa yóò kórìíra.
Yalghan sözligüchilerning hemmisini halak qilisen; Perwerdigar qanxor, aldamchi kishilerge nepret qilur.
7 Ṣùgbọ́n èmi, nípa títóbi àánú rẹ̀, èmi yóò wá sínú ilé rẹ̀; ní tọ̀wọ̀tọ̀wọ̀ ni èmi yóò tẹríba sí ìhà tẹmpili mímọ́ rẹ̀.
Biraq men bolsam, méhri-shepqitingning kengrichilikidin öyüngge kirimen; Sanga bolghan eyminishtin muqeddes ibadetxananggha qarap sejde qilimen;
8 Tọ́ mi, Olúwa, nínú òdodo rẹ, nítorí àwọn ọ̀tá mi, mú ọ̀nà rẹ tọ́ níwájú mi.
Méni öch körgenler tüpeylidin Öz heqqaniyliqing bilen méni yétekligeysen, i Perwerdigar; Yolungni aldimda tüz qilghin.
9 Kò sí ọ̀rọ̀ kan ní ẹnu wọn tí a lè gbàgbọ́; ọkàn wọn kún fún ìparun. Ọ̀nà ọ̀fun wọn ni isà òkú tí ó ṣí sílẹ̀; pẹ̀lú ahọ́n wọn ni wọ́n ń sọ ẹ̀tàn.
Chünki ularning aghzida héchqandaq semimiylik yoqtur; Ularning ichki dunyasi bolsa pasiqliqtur, Ularning galliri échilghan qebridek sésiqtur, Ular tili bilen xushamet qiliwatidu.
10 Dá wọn lẹ́bi Ọlọ́run! Jẹ́ kí rìkíṣí wọn jẹ́ ìṣubú wọn. Lé wọn jáde nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀ṣẹ̀ wọn, nítorí wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí ọ.
Ularning gunahini békitkeysen, i Xuda; Ular öz pilanliri bilen özliri mollaq atsun; Ularni özlirining nurghunlighan itaetsizlikliri bilen heydep chiqarghaysen; Chünki ular Sanga asiyliq qildi.
11 Ṣùgbọ́n, jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ó sádi ọ́ kí ó yọ̀; jẹ kí wọn máa kọrin fún ayọ̀ títí. Tan ààbò rẹ sórí wọn, àti àwọn tí ó fẹ́ràn orúkọ rẹ yóò máa yọ̀ nínú rẹ.
Shundaq qilghanda Sanga tayan’ghanlarning hemmisi shadlinidu; Ular menggü shadliq bilen tentene qilidu; Sen ularni qoghdaysen; Séning namingni söygenler séningdin yayraydu.
12 Dájúdájú, Olúwa, ìwọ bùkún olódodo; ìwọ fi ojúrere rẹ yí wọn ká bí asà.
Chünki Sen, i Perwerdigar, heqqaniy ademge bext ata qilisen; Uni shapaiting bilen qalqan kebi oraysen.

< Psalms 5 >